< 1 Crónicas 3 >
1 Éstos son los hijos de David que le nacieron en Hebrón: Amnón, el primogénito, de Ahinoam jezreelita; el segundo, Daniel, de Abigail la de Carmel;
Àwọn wọ̀nyí sì ni ọmọ Dafidi tí a bí fún un ní Hebroni. Àkọ́bí sì ni Amnoni ọmọ Ahinoamu ti Jesreeli; èkejì sì ni Daniẹli ọmọ Abigaili ará Karmeli;
2 el tercero, Absalón, hijo de Maaca, hija de Talmai, rey de Gesur; el cuarto, Adonías, hijo de Haguit;
ẹ̀kẹta sì ni Absalomu ọmọ Maaka ọmọbìnrin Talmai ọba Geṣuri bí fún un; ẹ̀kẹrin sì ni Adonijah ọmọ Haggiti;
3 el quinto, Sefatías, de Abital; el sexto, Itream, de su esposa Egla.
ẹ̀karùnún ni Ṣefatia láti ọ̀dọ̀ Abitali; àti ẹ̀kẹfà, Itreamu, láti ọ̀dọ̀ Egla aya rẹ̀.
4 Estos seis le nacieron en Hebrón, donde reinó siete años y seis meses. Luego reinó en Jerusalén 33 años.
Àwọn mẹ́fà wọ̀nyí ni a bí fún Dafidi ni Hebroni, níbi tí ó ti jẹ ọba fún ọdún méje àti oṣù mẹ́fà. Dafidi sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́tàlélọ́gbọ̀n.
5 Estos cuatro le nacieron en Jerusalén, de Betsabé, hija de Amiel: Simea, Sobab, Natán y Salomón.
Wọ̀nyí ni ọmọ wẹ́wẹ́ tí a bí fún un ní Jerusalẹmu: Ṣimea, Ṣobabu, Natani àti Solomoni. Àwọn mẹ́rin wọ̀nyí sì ni a bí láti ọ̀dọ̀ Bati-Ṣua ọmọbìnrin Ammieli.
6 Y otros nueve: Ibhar, Elisama, Elifelet,
Ibhari sì wà pẹ̀lú, Eliṣama, Elifeleti,
8 Elisama, Eliada y Elifelet.
Eliṣama, Eliada àti Elifeleti mẹ́sàn-án ni wọ́n.
9 Todos éstos fueron los hijos de David, sin contar los hijos de las concubinas. Tamar fue sobrina de ellos.
Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Dafidi yàtọ̀ sí àwọn ọmọ tí àlè bí fún un. Tamari sì ni arábìnrin wọn.
10 Roboam fue hijo de Salomón, cuyo hijo fue Abías, e hijo de éste Asa, cuyo hijo fue Josafat,
Ọmọ Solomoni ni Rehoboamu, Abijah ọmọ rẹ̀, Asa ọmọ rẹ̀, Jehoṣafati ọmọ rẹ̀,
11 de quien fue hijo Joram, cuyo hijo fue Ocozías, e hijo de éste Joás,
Jehoramu ọmọ rẹ̀, Ahasiah ọmọ rẹ̀, Joaṣi ọmọ rẹ̀,
12 del cual fue hijo Amasías, e hijo de éste Azarías, cuyo hijo fue Jotam.
Amasiah ọmọ rẹ̀, Asariah ọmọ rẹ̀, Jotamu ọmọ rẹ̀,
13 Hijo de éste fue Acaz, del cual fue hijo Ezequías, cuyo hijo fue Manasés,
Ahasi ọmọ rẹ̀, Hesekiah ọmọ rẹ̀, Manase ọmọ rẹ̀,
14 del cual fue hijo Amón, cuyo hijo fue Josías.
Amoni ọmọ rẹ̀, Josiah ọmọ rẹ̀.
15 Hijos de Josías: Johanán, su primogénito, el segundo Joacim, el tercero Sedequías, el cuarto Salum.
Àwọn ọmọ Josiah: àkọ́bí ọmọ rẹ̀ ni Johanani, èkejì ọmọ rẹ̀ ni Jehoiakimu, ẹ̀kẹta ọmọ rẹ̀ ni Sedekiah, ẹ̀kẹrin ọmọ rẹ̀ ni Ṣallumu.
16 Hijos de Joacim: Jeconías, cuyo hijo fue Sedequías.
Àwọn ìran ọmọ Jehoiakimu: Jekoniah ọmọ rẹ̀, àti Sedekiah.
17 Hijos de Jeconías el cautivo: Salatiel,
Àwọn ọmọ Jekoniah tí a mú ní ìgbèkùn: Ṣealitieli ọmọ rẹ̀ ọkùnrin,
18 Malquiram, Pedaías, Senazar, Jecamías, Hosama y Nedabías.
Malkiramu, Pedaiah, Ṣenasari, Jekamiah, Hoṣama àti Nedabiah.
19 Hijos de Pedaías: Zorobabel y Simei. E hijos de Zorobabel: Mesulam, Hananías y Selomit, su hermana.
Àwọn ọmọ Pedaiah: Serubbabeli àti Ṣimei. Àwọn ọmọ Serubbabeli: Meṣullamu àti Hananiah. Ṣelomiti ni arábìnrin wọn.
20 También estos cinco: Hasuba, Ohel, Berequías, Hasadías y Jusab-hesed.
Àwọn márùn-ún mìíràn sì tún wà: Haṣuba, Oheli, Berekiah, Hasadiah àti Jusabhesedi.
21 E hijos de Hananías: Pelatías y Jesaías; su hijo, Refaías; su hijo, Arnán; su hijo, Abdías; su hijo, Secanías.
Àwọn ọmọ Hananiah: Pelatiah àti Jeṣaiah, àti àwọn ọmọ Refaiah, ti Arnani, ti Obadiah àti ti Ṣekaniah.
22 Hijo de Secanías fue Semaías; e hijos de Semaías: Hatús, Igal, Barías, Nearías y Safat: seis.
Àwọn ọmọ Ṣekaniah: Ṣemaiah àti àwọn ọmọ rẹ̀: Hattusi, Igali, Bariah, Neariah àti Ṣafati, mẹ́fà ni gbogbo wọn.
23 Hijos de Nearías fueron estos tres: Elioenai, Ezequías y Azricam.
Àwọn ọmọ Neariah: Elioenai; Hesekiah, àti Asrikamu, mẹ́ta ni gbogbo wọn.
24 Hijos de Elioenai fueron estos siete: Hodavías, Eliasib, Pelaías, Acub, Johanán, Dalaías y Anani.
Àwọn ọmọ Elioenai: Hodafiah, Eliaṣibu, Pelaiah, Akkubu, Johanani, Delaiah àti Anani, méje sì ni gbogbo wọn.