< Esdras 2 >

1 Estos son los hijos de la provincia que subieron del cautiverio de los deportados, que Nabucodonosor, rey de Babilonia, había llevado a Babilonia, y que volvieron a Jerusalén y a Judá, cada uno a su ciudad;
Lákòókò náà, wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn agbègbè Juda tí ó gòkè wá láti ìgbèkùn láàrín àwọn tí a kó lọ, ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli ti fi agbára mú ní ìgbèkùn lọ sí Babeli (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀.
2 que vinieron con Zorobabel, Jesúa, Nehemías, Seraías, Reelaías, Mardoqueo, Bilsán, Mispar, Bigvai, Rehum y Baana. El número de los hombres del pueblo de Israel:
Àwọn wọ̀nyí bá Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Seraiah, Reelaiah, Mordekai, Bilṣani, Mispari, Bigfai, Rehumu àti Baanah wá). Iye àwọn ọkùnrin àwọn ènìyàn Israẹli.
3 Los hijos de Paros, dos mil ciento setenta y dos.
Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó lé méjìléláàádọ́sàn-án
4 Los hijos de Sefatías, trescientos setenta y dos.
Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá
5 Los hijos de Ara, setecientos setenta y cinco.
Arah jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
6 Los hijos de Pahatmoab, de los hijos de Jesúa y de Joab, dos mil ochocientos doce.
Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ àwọn ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹgbẹ̀rin lé méjìlá
7 Los hijos de Elam, mil doscientos cincuenta y cuatro.
Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin
8 Los hijos de Zattu, novecientos cuarenta y cinco.
Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún
9 Los hijos de Zacarías, setecientos sesenta.
Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin
10 Los hijos de Bani, seiscientos cuarenta y dos.
Bani jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì
11 Los hijos de Bebai, seiscientos veintitrés.
Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mẹ́tàlélógún
12 Los hijos de Azgad, mil doscientos veintidós.
Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé méjìlélógún
13 Los hijos de Adonikam, seiscientos sesenta y seis.
Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà
14 Los hijos de Bigvai, dos mil cincuenta y seis.
Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
15 Los hijos de Adin, cuatrocientos cincuenta y cuatro.
Adini jẹ́ àádọ́ta lé ní irinwó ó lé mẹ́rin
16 Los hijos de Ater, de Ezequías, noventa y ocho.
Ateri (nípasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́run
17 Los hijos de Bezai, trescientos veintitrés.
Besai jẹ́ ọrùndínnírinwó ó lé mẹ́ta
18 Los hijos de Jorah, ciento doce.
Jora jẹ́ méjìléláàádọ́fà
19 Los hijos de Hasum, doscientos veintitrés.
Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
20 Los hijos de Gibbar, noventa y cinco.
Gibbari jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn.
21 Los hijos de Belén, ciento veintitrés.
Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà
22 Los de Netofa, cincuenta y seis.
Netofa jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
23 Los de Anatot, ciento veintiocho.
Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje
24 Los hijos de Azmavet, cuarenta y dos.
Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì
25 Los hijos de Quiriat Arim, Chefira y Beerot, setecientos cuarenta y tres.
Kiriati-Jearimu, Kefira àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta
26 Los hijos de Ramá y Geba, seiscientos veintiuno.
Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún
27 Los varones de Micmas, ciento veintidós.
Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà
28 Los varones de Betel y de Hai, doscientos veintitrés.
Beteli àti Ai jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
29 Los hijos de Nebo, cincuenta y dos.
Nebo jẹ́ méjìléláàádọ́ta
30 Los hijos de Magbis, ciento cincuenta y seis.
Magbiṣi jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́jọ
31 Los hijos del otro Elam, mil doscientos cincuenta y cuatro.
Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta
32 Los hijos de Harim, trescientos veinte.
Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó.
33 Los hijos de Lod, Hadid y Ono, setecientos veinticinco.
Lodi, Hadidi àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún
34 Los hijos de Jericó, trescientos cuarenta y cinco.
Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún
35 Los hijos de Senaa, tres mil seiscientos treinta.
Senaa jẹ́ egbèji dín lógún ó lé ọgbọ̀n.
36 Los sacerdotes: los hijos de Jedaías, de la casa de Jesúa, novecientos setenta y tres.
Àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje
37 Los hijos de Immer, mil cincuenta y dos.
Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì
38 Los hijos de Pashur, mil doscientos cuarenta y siete.
Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta
39 Los hijos de Harim, mil diecisiete.
Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún.
40 Los levitas: los hijos de Jesúa y de Cadmiel, de los hijos de Hodavías, setenta y cuatro.
Àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ọmọ Jeṣua àti Kadmieli (ti ìdílé Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin.
41 Los cantores: los hijos de Asaf, ciento veintiocho.
Àwọn akọrin. Àwọn ọmọ Asafu jẹ́ méjìdínláàádóje.
42 Los hijos de los porteros: los hijos de Salum, los hijos de Ater, los hijos de Talmón, los hijos de Acub, los hijos de Hatita, los hijos de Sobai, en total ciento treinta y nueve.
Àwọn aṣọ́bodè. Àwọn ará Ṣallumu, Ateri, Talmoni, Akkubu, Hatita àti Ṣobai jẹ́ mọ́kàndínlógóje.
43 Los servidores del templo: los hijos de Ziha, los hijos de Hasupha, los hijos de Tabbaoth,
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili. Àwọn ọmọ. Siha, Hasufa, Tabboati,
44 los hijos de Keros, los hijos de Siaha, los hijos de Padon,
Kerosi, Siaha, Padoni,
45 los hijos de Lebanah, los hijos de Hagabah, los hijos de Akkub,
Lebana, Hagaba, Akkubu,
46 los hijos de Hagab, los hijos de Shamlai, los hijos de Hanan,
Hagabu, Ṣalmai, Hanani,
47 los hijos de Giddel, los hijos de Gahar, los hijos de Reaiah,
Giddeli, Gahari, Reaiah,
48 los hijos de Rezin, los hijos de Nekoda, los hijos de Gazzam,
Resini, Nekoda, Gassamu,
49 los hijos de Uzza, los hijos de Paseah, los hijos de Besai,
Ussa, Pasea, Besai,
50 los hijos de Asna, los hijos de Meunim, los hijos de Nefisim,
Asna, Mehuni, Nefisimu,
51 los hijos de Bakbuk, los hijos de Hakupha, los hijos de Harhur,
Bakbu, Hakufa, Harhuri.
52 los hijos de Bazluth, los hijos de Mehida, los hijos de Harsha,
Basluti, Mehida, Harṣa,
53 los hijos de Barkos, los hijos de Sisera, los hijos de Temah,
Barkosi, Sisera, Tema,
54 los hijos de Neziah, los hijos de Hatipha.
Nesia àti Hatifa.
55 Los hijos de los siervos de Salomón: los hijos de Sotai, los hijos de Hassophereth, los hijos de Peruda,
Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. Àwọn ọmọ Sotai, Sofereti, Peruda,
56 los hijos de Jaalah, los hijos de Darkon, los hijos de Giddel,
Jaala, Darkoni, Giddeli,
57 los hijos de Sefatías, los hijos de Hattil, los hijos de Pochereth Hazzebaim, los hijos de Ami.
Ṣefatia, àwọn ọmọ Hattili, Pokereti ti Haṣebaimu àti àwọn ọmọ Ami.
58 Todos los servidores del templo, y los hijos de los servidores de Salomón, fueron trescientos noventa y dos.
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ.
59 Estos fueron los que subieron de Tel Melá, Tel Harsa, Querubín, Addán e Immer; pero no pudieron mostrar las casas de sus padres ni su descendencia, si eran de Israel:
Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
60 los hijos de Delaía, los hijos de Tobías, los hijos de Necoda, seiscientos cincuenta y dos.
Àwọn ọmọ Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì.
61 De los hijos de los sacerdotes: los hijos de Habaía, los hijos de Hakkoz, y los hijos de Barzilai, que tomó mujer de las hijas de Barzilai Galaadita, y se llamó como ellas.
Àti nínú àwọn ọmọ àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ: Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin tí ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi a sì ń fi orúkọ náà pè é).
62 Estos buscaron su lugar entre los que estaban registrados por genealogía, pero no fueron encontrados; por lo tanto, fueron considerados descalificados y apartados del sacerdocio.
Àwọn wọ̀nyí wá ìwé ìrántí ìdílé wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni a kò kà wọ́n kún ara àlùfáà nítorí, a kà wọ́n sí aláìmọ́.
63 El gobernador les dijo que no debían comer de las cosas más santas hasta que se levantara un sacerdote para servir con Urim y con Tumim.
Baálẹ̀ pa á láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ nínú oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí àlùfáà kan yóò fi ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu.
64 Toda la asamblea reunida era de cuarenta y dos mil trescientos sesenta,
Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó.
65 además de sus siervos y siervas, que eran siete mil trescientos treinta y siete; y tenían doscientos cantores y cantoras.
Yàtọ̀ sí ẹgbẹ̀rin dín lẹ́gbàárin ó dín mẹ́tàlélọ́gọ́ta ìránṣẹ́ ọkùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin; wọ́n ní igba akọrin ọkùnrin àti obìnrin.
66 Sus caballos eran setecientos treinta y seis; sus mulos, doscientos cuarenta y cinco;
Wọ́n ní ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin ẹṣin; ìbáaka òjìlélúgba ó lé márùn-ún,
67 sus camellos, cuatrocientos treinta y cinco; sus asnos, seis mil setecientos veinte.
ràkunmí jẹ́ irinwó ó lé márùndínlógójì àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rin lé lọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin.
68 Algunos de los jefes de familia de los padres, cuando llegaron a la casa de Yahvé que está en Jerusalén, ofrecieron voluntariamente por la casa de Dios para levantarla en su lugar.
Ní ìgbà tí wọ́n dé ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, díẹ̀ nínú àwọn olórí àwọn ìdílé fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ fún ṣíṣe àtúnkọ́ ilé Ọlọ́run ní ààyè rẹ̀.
69 Dieron, según su capacidad, para el tesoro de la obra, sesenta y un mil dáricos de oro, cinco mil minas de plata, y cien vestidos sacerdotales.
Gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, wọ́n fún ilé ìṣúra fún iṣẹ́ yìí ní ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ́gbẹ̀rún ìwọ̀n dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún márùn-ún fàdákà àti ọgọ́rùn-ún ẹ̀wù àlùfáà.
70 Así que los sacerdotes y los levitas, con parte del pueblo, los cantores, los porteros y los servidores del templo, vivían en sus ciudades, y todo Israel en sus ciudades.
Àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́bodè àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa ṣe àtìpó sínú àwọn ìlú wọn, pẹ̀lú àwọn ènìyàn mìíràn, àti ìyókù àwọn ọmọ Israẹli ṣe àtìpó sínú ìlú u wọn.

< Esdras 2 >