< Nehemija 10 >
1 Torej tisti, ki so pečatili, so bili: Nehemija, Hahaljájev sin Tirsata, Sedekíja,
Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni: Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah. Sedekiah
2 Serajá, Azarjá, Jeremija,
Seraiah, Asariah, Jeremiah,
3 Pašhúr, Amarjá, Malkijá,
Paṣuri, Amariah, Malkiah,
Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
5 Harím, Meremót, Obadjá,
Harimu, Meremoti, Obadiah,
6 Daniel, Ginetón, Baruh,
Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
7 Mešulám, Abíja, Mijamín,
Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
8 Maazjá, Bilgáj, Šemajá. Ti so bili duhovniki.
Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.
9 Lévijevci: tako Azanjájev sin Ješúa, Binúj izmed Henadádovih sinov, Kadmiél,
Àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,
10 kakor njihovi bratje: Šebanjá, Hodijá, Kelitá, Pelajá, Hanán,
àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah, Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,
12 Zahúr, Šerebjá, Šebanjá,
Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
14 Vodje ljudstva: Paróš, Pahat Moáb, Elám, Zatú, Baní,
Àwọn olórí àwọn ènìyàn: Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,
16 Adoníja, Bigváj, Adín,
Adonijah, Bigfai, Adini,
20 Magpiáš, Mešulám, Hezír,
Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
21 Mešezabél, Cadók, Jadúa,
Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
22 Pelatjá, Hanán, Anajá,
Pelatiah, Hanani, Anaiah,
23 Hošéa, Hananjá, Hašúb,
Hosea, Hananiah, Haṣubu,
Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
25 Rehúm, Hašabná, Maasejá,
Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
27 Malúh, Harím in Baaná.
Malluki, Harimu, àti Baanah.
28 Preostanek ljudstva, duhovniki, Lévijevci, vratarji, pevci, Netinimci in vsi, ki so se ločili od ljudstva dežel k postavi Boga, njihove žene, njihovi sinovi in njihove hčere, vsak, ki je imel spoznanje in imel razumevanje,
“Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé
29 so se pridružili k svojim bratom, svojim plemičem in vstopili v prekletstvo in prisego, da se ravnajo po Božji postavi, ki je bila dana po Mojzesu, Božjemu služabniku in da obeležujejo in delajo vse zapovedi Gospoda, našega Gospoda, njegove sodbe in njegove zakone,
gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.
30 in da mi ne bi dajali svojih hčera ljudstvu dežele niti jemali njihovih hčera za naše sinove.
“A ti ṣe ìlérí pé, a kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn tí wọ́n wà ní àyíká wa bí ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.
31 Če ljudstvo dežele prinese blago ali kakršen koli živež na šabatni dan, da prodaja, da mi tega ne bomo kupovali od njih na šabat ali na sveti dan in da bomo pustili sedmo leto in izterjavo vsakega dolga.
“Nígbà tí àwọn ènìyàn àdúgbò bá mú ọjà tàbí oúnjẹ wá ní ọjọ́ ìsinmi láti tà, àwa kò ní rà á ní ọwọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tàbí ní ọjọ́ mímọ́ kankan. Ní gbogbo ọdún keje àwa kò ní ro ilẹ̀ náà, a ó sì pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.
32 Prav tako smo naredili odredbe za sebe, da se letno obremenimo s tretjino šekla za službo hiše svojega Boga,
“Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ pé, a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ní ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa:
33 za hlebe navzočnosti in za nenehno jedilno daritev in za nenehno žgalno daritev od šabat, od mlajev, za določene praznike, za svete stvari in za daritve za greh, da se naredi odkupitev za Izrael in za vse delo hiše svojega Boga.
nítorí oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún tí a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.
34 Vrgli smo žrebe med duhovniki, Lévijevci in ljudstvom za dar lesa, da bi ga prinašali v hišo svojega Boga, glede na hiše naših očetov, ob določenih časih, leto za letom, da [ga] zažigamo na oltarju Gospoda, svojega Boga, kakor je to zapisano v postavi
“Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò mú ọrẹ igi wá láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa sí ilé Ọlọ́run wa, ní àkókò tí a yàn ní ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin.
35 in da prinašamo prve sadove svojih tal in prve sadove vsega sadja od vseh dreves, leto za letom, v Gospodovo hišo.
“Àwa tún gbà ojúṣe láti mú àkọ́so àwọn èso wa wá àti gbogbo èso igi wá ní ilé Olúwa.
36 Tudi prvorojenca naših sinov in naše živine, kakor je to zapisano v postavi in prvence naših čred in naših tropov, da jih privedemo k hiši svojega Boga, k duhovnikom, ki služijo v hiši našega Boga
“Gẹ́gẹ́ bí a sì ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò mú àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ọ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, wá sí ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà tí ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.
37 In da naj bi prinesli prve sadove našega testa in naših daritev in sad vseh vrst dreves, od vina in od olja, k duhovnikom, k sobam hiše našega Boga in desetine naših tal k Lévijevcem, da bodo isti Lévijevci lahko imeli desetine v vseh mestih našega posevka.
“Síwájú sí i, àwa yóò mú àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò sì mú ìdámẹ́wàá ohun ọ̀gbìn wá fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá ní gbogbo àwọn ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́.
38 Duhovnik, Aronov sin, bo z Lévijevci, ko bodo Lévijevci prejemali desetine in Lévijevci bodo prinesli gor desetino od desetin k hiši našega Boga, k sobam, v zakladno hišo.
Àlùfáà tí o ti ìdílé Aaroni wá ni yóò wá pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nígbà tí wọ́n bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò sì mú ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà wá sí ilé Ọlọ́run, sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí inú ilé ìṣúra.
39 Kajti Izraelovi otroci in Lévijevi otroci bodo prinašali daritev žita, od novega vina in olja, v sobe, kjer so posode svetišča in duhovniki, ki služijo in vratarji in pevci. Ne bomo zapustili hiše svojega Boga.
Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ mú ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí níbi tí a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ sí àti ibi tí àwọn àlùfáà tí ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́nà àti àwọn akọrin máa ń dúró sí. “Àwa kì yóò gbàgbé tàbí ṣe àìbìkítà nípa ilé Ọlọ́run wa.”