< Ozej 8 >
1 Nastavi šofar k svojim ustom. Prišel bo kakor orel zoper Gospodovo hišo, zato ker so prekršili mojo zavezo in se prekršili zoper mojo postavo.
“Fi ìpè sí ẹnu rẹ! Ẹyẹ idì wà lórí ilé Olúwa nítorí pé àwọn ènìyàn ti dalẹ̀ májẹ̀mú, wọ́n sì ti ṣọ̀tẹ̀ sí òfin mi.
2 Izrael bo klical k meni: ›Moj Bog, mi te poznamo.‹
Israẹli kígbe pè mí, ‘Ọlọ́run wa, àwa mọ̀ ọ́n!’
3 Izrael je zavrgel stvar, ki je dobra; sovražnik ga bo zasledoval.
Ṣùgbọ́n Israẹli ti kọ ohun tí ó dára sílẹ̀ ọ̀tá yóò sì máa lépa rẹ̀.
4 Nastavljali so si kralje, toda ne po meni. Nameščali so si prince, jaz pa tega nisem vedel. Iz svojega srebra in svojega zlata so si delali malike, da bi bili lahko iztrebljeni.
Wọ́n fi àwọn ọba jẹ ṣùgbọ́n, kì í ṣe nípasẹ̀ mi wọ́n yan ọmọ-aládé láì si ìmọ̀ mi níbẹ̀. Wọ́n fi fàdákà àti wúrà ṣe ère fún ara wọn, si ìparun ara wọn.
5 Tvoje tele, oh Samarija, te je zavrglo. Moja jeza se je vnela zoper njih. Kako dolgo bo, preden se bodo dokopali do nedolžnosti?
Ju ère ẹgbọrọ màlúù rẹ, ìwọ Samaria! Ìbínú mi ń ru sí wọn: yóò ti pẹ́ tó kí wọ́n tó dé ipò àìmọ̀kan?
6 Kajti tudi to je bilo iz Izraela; delavec ga je naredil, zato to ni Bog, temveč bo tele iz Samarije zlomljeno na koščke.
Israẹli ni wọ́n ti wá! Ère yìí agbẹ́gilére ló ṣe é, àní ère ẹgbọrọ màlúù Samaria, ni a ó fọ́ túútúú.
7 Kajti sejali so veter, želi bodo pa vihar. Ta nima stebla, brst ne obrodi moke. Če bo tako, da obrodi, ga bodo pogoltnili tujci.
“Wọ́n gbin afẹ́fẹ́ wọ́n sì ká ìjì. Igi ọkà kò lórí, kò sì ní mú oúnjẹ wá. Bí ó bá tilẹ̀ ní ọkà àwọn àjèjì ni yóò jẹ.
8 Izrael je požrt; sedaj bodo med pogani kakor posoda, v kateri ni zadovoljstva.
A ti gbé Israẹli mì, báyìí, ó sì ti wà láàrín àwọn orílẹ̀-èdè bí ohun èlò tí kò wúlò.
9 Kajti šli so gor v Asirijo, osamljen divji osel sam zase. Efrájim si je najel ljubimce.
Nítorí pé wọ́n ti gòkè lọ sí Asiria gẹ́gẹ́ bí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó tó ń rìn kiri. Efraimu ti ta ara rẹ̀ fún àwọn olólùfẹ́ rẹ̀.
10 Da, čeprav so najemali med narodi, jih bom sedaj zbral in bodo malce žalovali zaradi bremena kralja princev.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ti ta ara wọn sí àárín Orílẹ̀-èdè, Èmi ó ṣà wọ́n jọ nísinsin yìí. Wọn ó sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣòfò dànù lọ́wọ́ ìnilára ọba alágbára.
11 Ker je Efrájim naredil mnogo oltarjev za greh, bodo oltarji njemu v greh.
“Nítorí Efraimu ti kọ́ pẹpẹ púpọ̀ fún ìrúbọ ẹ̀ṣẹ̀ gbogbo rẹ̀ ti di pẹpẹ ìdẹ́ṣẹ̀ fún un
12 Njemu sem napisal velike stvari iz svoje postave, vendar so bile štete kakor čudna stvar.«
Mo kọ ọ̀pọ̀lọpọ̀ ohun tí ó jẹ́ òfin mi fún wọn, ṣùgbọ́n wọn kà á sí ohun àjèjì.
13 Žrtvujejo meso za klavno daritev mojih daritev in ga jedo, toda Gospod jih ne sprejema. Sedaj se bo spomnil njihove krivičnosti in obiskal njihove grehe; vrnili se bodo v Egipt.
Wọ́n ń rú ẹbọ tí wọ́n yàn fún mi, wọ́n sì ń jẹ ẹran ibẹ̀, ṣùgbọ́n inú Olúwa kò dùn sí wọn. Báyìí yóò rántí ìwà búburú wọn yóò sì jẹ wọ́n ní yà fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Wọn yóò padà sí Ejibiti.
14 »Kajti Izrael je pozabil svojega Stvarnika in zgradil templje in Juda je pomnožil utrjena mesta, toda na njegova mesta bom poslal ogenj in ta bo požrl njegove palače.
Nítorí Israẹli ti gbàgbé ẹlẹ́dàá rẹ̀ Ó sì ń kọ́ ààfin púpọ̀ Juda ti kọ́ ìlú olódi púpọ̀ ṣùgbọ́n èmi ó rán iná kan sí orí àwọn ìlú rẹ̀ èyí tí yóò jẹ ibi agbára rẹ̀ run.”