< Psalmi 85 >

1 Smilovao si se, Gospode, na zemlju svoju, povratio si roblje Jakovljevo.
Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Saamu. Ìwọ fi ojúrere hàn fún ilé rẹ, Olúwa; ìwọ mú ohun ìní Jakọbu bọ̀ sí ipò.
2 Prostio si nepravdu narodu svojemu, pokrio si sve grijehe njegove.
Ìwọ dárí àìṣedéédéé àwọn ènìyàn rẹ jì ìwọ sì bó ẹ̀ṣẹ̀ wọn mọ́lẹ̀. (Sela)
3 Ustavio si svu jarost svoju, ublažio žestinu gnjeva svojega.
Ìwọ fi àwọn ìbínú rẹ sápá kan ìwọ sì yípadà kúrò nínú ìbínú gbígbóná rẹ.
4 Povrati nas, Bože spasitelju naš, prekini srdnju svoju na nas.
Yí wa padà, Ọlọ́run ìgbàlà wa, kí o sì yí ìbínú rẹ̀ padà kúrò lọ́dọ̀ wa.
5 Zar æeš se dovijeka gnjeviti na nas, i protegnuti gnjev svoj od koljena na koljeno?
Ìwọ yóò ha máa bínú sí wa títí láé? Ìwọ yóò ha mú ìbínú rẹ pẹ́ yí gbogbo ìran ká?
6 Zar se neæeš povratiti i oživiti nas, da bi se narod tvoj radovao o tebi?
Ìwọ kì yóò ha sọ wá jí padà mọ́, pé kí àwọn ènìyàn rẹ lè yọ nínú rẹ?
7 Pokaži nam, Gospode, milost svoju, i pomoæ svoju daj nam.
Fi ìfẹ́ rẹ tí kò le è kùnà hàn wá, Olúwa, kí o sì fún wa ní ìgbàlà rẹ.
8 Da poslušam što govori Gospod Bog. On izrièe mir narodu svojemu i svecima svojim, i onima koji se obraæaju srcem k njemu.
Èmi ó gbọ́ ohun tí Olúwa Ọlọ́run yóò wí; ó ṣèlérí àlàáfíà fún àwọn ènìyàn rẹ̀, àní ẹni mímọ́ rẹ̀, ṣùgbọ́n má ṣe jẹ́ kí wọn padà sí àìmoye.
9 Da, blizu je onijeh koji ga se boje pomoæ njegova, da bi naselio slavu u zemlji našoj!
Nítòótọ́ ìgbàlà rẹ̀ súnmọ́ àwọn tí ó bẹ̀rù rẹ̀, pé kí ògo rẹ̀ kí ó lè gbé ní ilẹ̀ wa.
10 Milost i istina srešæe se, pravda i mir poljubiæe se.
Ìfẹ́ àti òtítọ́ parapọ̀; òdodo àti àlàáfíà fẹnu ko ara wọn.
11 Istina æe niknuti iz zemlje i pravda æe s neba priniknuti.
Òtítọ́ ń sun jáde láti ilẹ̀ wá òdodo sì bojú wolẹ̀ láti ọ̀run.
12 I Gospod æe dati dobro, i zemlja naša daæe plod svoj.
Olúwa yóò fi ohun dídára fún ni nítòótọ́, ilẹ̀ wa yóò sì mú ìkórè rẹ̀ jáde.
13 Pravda æe pred njim iæi, i postaviæe na put stope svoje.
Òdodo síwájú rẹ lọ o sì pèsè ọ̀nà fún ìgbésẹ̀ rẹ̀.

< Psalmi 85 >