< Brojevi 27 >
1 Tada doðoše kæeri Salpada sina Ofera sina Galada sina Mahira sina Manasijina, od plemena Manasije sina Josifova, a imena im bjehu Mala, Nuja, Egla, Melha i Tersa.
Ọmọbìnrin Selofehadi ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri ọmọ Manase tó jẹ́ ìdílé Manase, ọmọ Josẹfu wá. Orúkọ àwọn ọmọbìnrin náà ni Mahila, Noa, Hogla, Milka àti Tirsa.
2 I stadoše pred Mojsija i pred Eleazara sveštenika i pred knezove i sav zbor na vratima šatora od sastanka, i rekoše:
Wọ́n súnmọ́ ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé wọ́n sì dúró níwájú Mose, àti Eleasari àlùfáà, àti níwájú àwọn olórí àti ìjọ, wọ́n sì wí pé,
3 Otac naš umrije u pustinji, ali ne bješe u društvu s onima koji se pobuniše na Gospoda u buni Korejevoj, nego umrije od grijeha svojega, a ne ostavi sinova.
“Baba wa kú sí aginjù. Kò sí lára àwọn ẹgbẹ́ Kora tí wọ́n kó ara wọn pọ̀ lòdì sí Olúwa, ṣùgbọ́n ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ kò sì fi ọmọkùnrin sílẹ̀.
4 Zašto da se istrijebi ime oca našega iz porodice njegove zato što nije imao sina? Daj nam našljedstvo meðu braæom oca našega.
Kín ni ó dé tí orúkọ baba wa yóò parẹ́ nínú ìdílé rẹ̀ nítorí pé kò ní ọmọkùnrin? Fún wa ní ilẹ̀ ìní láàrín àwọn arákùnrin baba wa.”
5 I iznese Mojsije stvar njihovu pred Gospoda.
Nígbà náà Mose mú ọ̀rọ̀ wọn wá síwájú Olúwa.
6 A Gospod reèe Mojsiju govoreæi:
Olúwa sì wí fún un pé,
7 Pravo govore kæeri Salpadove; podaj im pravo da imaju našljedstvo meðu braæom oca svojega, i prenesi našljedstvo oca njihova na njih.
“Ohun tí àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ń sọ tọ̀nà. O gbọdọ̀ fún wọn ní ogún ìní ti baba wọn.
8 A sinovima Izrailjevijem kaži i reci: kad ko umre a nema sina, onda prenesite našljedstvo njegovo na kæer njegovu;
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ‘Tí ọkùnrin kan bá kú tí kò sì fi ọmọkùnrin sáyé, ẹ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ ní ogún ìní rẹ̀.
9 Ako li ni kæeri nema, onda podajte našljedstvo njegovo braæi njegovoj;
Tí kò bá ní ọmọbìnrin, fi ohun ìní rẹ́ fún àwọn arákùnrin rẹ̀.
10 Ako li ni braæe nema, onda podajte našljedstvo njegovo braæi oca njegova;
Tí kò bá ní arákùnrin, fi ogún ìní rẹ̀ fún arákùnrin baba rẹ̀.
11 Ako li nema ni braæe oèine, onda podajte našljedstvo njegovo onomu ko mu je najbliži u rodu njegovu, i neka je njegovo. I to neka bude sinovima Izrailjevijem zakon za suðenje, kako zapovjedi Gospod Mojsiju.
Tí baba rẹ̀ kò bá ní arákùnrin, fún ará ilé rẹ̀ tí ó bá súnmọ́ jù ní ìdílé rẹ̀ ní ogún ìní rẹ̀, kí ó lè jogún rẹ̀. Èyí gbọdọ̀ jẹ́ ìlànà ìdájọ́ fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.’”
12 Još reèe Gospod Mojsiju: izidi na goru ovu Avarimsku, i vidi zemlju koju sam dao sinovima Izrailjevijem.
Nígbà náà Olúwa sọ fún Mose pé, “Lọ sì orí òkè Abarimu yìí, kí o sì lọ wo ilẹ̀ tí mo fún àwọn ọmọ Israẹli.
13 I kad je vidiš, pribraæeš se k rodu svojemu i ti, kao što se pribrao Aron brat tvoj.
Lẹ́yìn ìgbà tí o bá sì ti rí i, ìwọ náà yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn rẹ gẹ́gẹ́ bí Aaroni arákùnrin rẹ ṣe ṣe,
14 Jer ne poslušaste rijeèi moje u pustinji Sinu u svaði narodnoj, kad je trebalo da me proslavite na vodi pred oèima njihovijem. To je voda od svaðe u Kadisu u pustinji Sinu.
nítorí nígbà tí ìlú ṣọ̀tẹ̀ níbi omi ní aginjù Sini, tí gbogbo yín ṣe àìgbọ́ràn sí mi láti yà mí sí mímọ́ níwájú wọn.” (Èyí ni omi Meriba ní Kadeṣi ní aginjù Sini.)
15 I reèe Mojsije Gospodu govoreæi:
Mose sọ fún Olúwa wí pé,
16 Gospode Bože duhovima i svakom tijelu, postavi èovjeka nad ovijem zborom,
“Jẹ́ kí Olúwa, Ọlọ́run ẹ̀mí gbogbo ènìyàn, kí ó yan ọkùnrin kan sí orí ìjọ ènìyàn yìí,
17 Koji æe izlaziti pred njima i koji æe dolaziti pred njima, koji æe ih izvoditi i opet dovoditi, da ne bi bio zbor Gospodnji kao ovce koje nemaju pastira.
láti máa darí wọn, ẹni tí yóò mú wọn jáde, tí yóò sì mú wọn wọlé, gbogbo ènìyàn Olúwa kí yóò dàbí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́.”
18 A Gospod reèe Mojsiju: uzmi k sebi Isusa sina Navina, èovjeka u kom je duh moj, i metni ruku svoju na nj,
Nígbà náà ní Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú Joṣua ọmọ Nuni, ọkùnrin nínú ẹni tí èmi wà, kí o sì gbé ọwọ́ rẹ lé e.
19 I izvedi ga pred Eleazara sveštenika i pred sav zbor, i podaj mu zapovijesti pred njima.
Jẹ́ kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti ojú gbogbo àwọn ìjọ ènìyàn Israẹli kí o sì fi àṣẹ fún un ní ojú wọn.
20 I podaj mu od slave svoje, da ga sluša sav zbor sinova Izrailjevijeh.
Kí ìwọ kí ó sì fi nínú ọláńlá rẹ sí i lára, kí gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli kí ó lè gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu.
21 I neka staje pred Eleazara sveštenika da ga pita za sud Urim pred Gospodom; po zapovijesti njegovoj neka polaze i po zapovijesti njegovoj neka dolaze on i svi sinovi Izrailjevi s njim i sav zbor.
Kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà, tí yóò gba ìpinnu fún láti béèrè Urimu níwájú Olúwa. Gẹ́gẹ́ bí òfin yìí ni òun pẹ̀lú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli yóò jáde lọ, pẹ̀lú òfin rẹ̀ sì ni wọn ó wọlé.”
22 I uèini Mojsije kako mu zapovjedi Gospod; i uzev Isusa postavi ga pred Eleazara sveštenika i pred sav zbor.
Mose sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ fún un. Ó mú Joṣua ó sì mú kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti níwájú gbogbo ìjọ.
23 I metnu ruke svoje na nj, i dade mu zapovijesti, kako bješe zapovjedio Gospod preko Mojsija.
Nígbà náà ni ó gbé ọwọ́ rẹ̀ le e, ó sì fi àṣẹ fún un gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.