< Jezekilj 35 >

1 Opet mi doðe rijeè Gospodnja govoreæi:
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2 Sine èovjeèji, okreni lice svoje prema gori Siru i prorokuj protiv nje.
“Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
3 I reci: ovako veli Gospod Gospod: evo me na tebe, goro Sire! i dignuæu ruku svoju na te, i opustiæu te sasvijem.
kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
4 Gradove æu tvoje opustiti, i ti æeš biti pustoš, i poznaæeš da sam ja Gospod.
Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
5 Što je u tebe vjeèno neprijateljstvo, i rasipaš sinove Izrailjeve maèem u nevolji njihovoj, kad je kraj bezakonju njihovu,
“‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
6 Zato, tako ja bio živ, govori Gospod Gospod, krvi æu te predati i krv æe te goniti, jer ne mrziš na krv, krv æe te goniti.
nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
7 I obratiæu goru Sir sasvijem u pustoš, da niko neæe dolaziti ni odlaziti.
Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
8 I napuniæu gore njezine pobijenijeh njezinijeh; na humovima tvojim i u dolinama tvojim i po svijem potocima tvojim padaæe pobijeni od maèa.
Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
9 Vjeènu pustinju naèiniæu od tebe i gradovi se tvoji neæe opraviti, i poznaæete da sam ja Gospod.
Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
10 Što govoriš: ova dva naroda i ove dvije zemlje moje æe biti, i naslijediæemo ih, ako i jest Gospod bio ondje,
“‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
11 Zato, tako ja živ bio, govori Gospod Gospod, uèiniæu po gnjevu tvom i po zavisti tvojoj, s kojom si postupala iz mržnje prema njima, i biæu poznat meðu njima kad ti sudim.
nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
12 I poznaæeš da sam ja Gospod èuo sve tvoje hule koje si govorila na gore Izrailjeve rekavši: opustješe, nama su dane da ih jedemo.
Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
13 I velièaste se suprot meni ustima svojim, i množiste na me rijeèi svoje; èuo sam.
Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
14 Ovako veli Gospod Gospod: kad se sva zemlja stane veseliti, tebe æu opustiti.
Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
15 Kako si se ti veselila našljedstvu doma Izrailjeva što opustje, tako æu i tebi uèiniti: opustjeæeš, goro Sire, i sva zemljo Edomska; i poznaæe se da sam ja Gospod.
Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”

< Jezekilj 35 >