< Izlazak 24 >

1 I reèe Mojsiju: izaði gore ka Gospodu ti i Aron i Nadav i Avijud i sedamdeset starješina Izrailjevih, i poklonite se izdaleka.
Ní ìgbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Gòkè tọ Olúwa wá, ìwọ àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli. Ẹ̀yin kì ó sìn ni òkèèrè réré.
2 I Mojsije sam neka pristupi ka Gospodu, a oni neka ne pristupe; i narod neka ne ide na gore s njim.
Ṣùgbọ́n Mose nìkan ṣoṣo ni yóò súnmọ́ Olúwa; àwọn tókù kò gbọdọ̀ súnmọ́ tòsí ibẹ̀. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn kò gbọdọ̀ gòkè wá pẹ̀lú rẹ̀.”
3 I doðe Mojsije, i kaza narodu sve rijeèi Gospodnje i sve zakone. I odgovori narod jednijem glasom i rekoše: èiniæemo sve što je rekao Gospod.
Nígbà ti Mose lọ láti sọ fún àwọn ènìyàn, gbogbo ọ̀rọ̀ àti òfin Olúwa, wọ́n wí ní ohùn kan pé, “Gbogbo ohun ti Olúwa wí ni àwa yóò ṣe.”
4 I napisa Mojsije sve rijeèi Gospodnje, i ustavši rano naèini oltar pod gorom i dvanaest stupova za dvanaest plemena Izrailjevih.
Nígbà náà ni Mose kọ gbogbo ohun tí Olúwa sọ sílẹ̀. Ó dìde ní kùtùkùtù òwúrọ̀ ọjọ́ kejì, ó sì mọ pẹpẹ ni ẹsẹ̀ òkè náà. Ó ṣe ọ̀wọ́n òkúta méjìlá. Èyí ti ó dúró fún àwọn ẹ̀yà Israẹli méjìlá.
5 I posla mladiæe izmeðu sinova Izrailjevih, koji prinesoše žrtve paljenice i prinesoše teoce na žrtve zahvalne Gospodu.
Nígbà náà ni ó rán àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin Israẹli, wọ́n sì rú ẹbọ sísun, wọ́n fi ọ̀dọ́ màlúù rú ẹbọ àlàáfíà si Olúwa.
6 I uzevši Mojsije polovinu krvi, metnu u zdjele, a polovinu krvi izli na oltar.
Mose bu ìlàjì ẹ̀jẹ̀ ẹran sínú abọ́, ó sì fi ìlàjì tókù wọn ara pẹpẹ.
7 I uze knjigu zavjetnu i proèita narodu. A oni rekoše: što je god rekao Gospod èiniæemo i slušaæemo.
Nígbà náà ni ó sì mú ìwé májẹ̀mú, ó sì kà á sí àwọn ènìyàn. Wọ́n dáhùn pé, “Àwa yóò ṣe gbogbo ohun tí Olúwa wí. Àwa yóò sì gbọ́rọ̀.”
8 A Mojsije uze krv, i pokropi njom narod, i reèe: evo krv zavjeta, koji uèini Gospod s vama za sve rijeèi ove.
Nígbà náà ni Mose gbé ẹ̀jẹ̀, ó sì wọn sí àwọn ènìyàn náà lára pé, “Èyí ni ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú tí Olúwa ti ṣe pẹ̀lú yín ni ìbámu pẹ̀lú àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí.”
9 Potom otide gore Mojsije i Aron, Nadav i Avijud, i sedamdeset starješina Izrailjevih.
Mose àti Aaroni, Nadabu àti Abihu àti àádọ́rin àwọn àgbàgbà Israẹli gòkè lọ.
10 I vidješe Boga Izrailjeva, i pod nogama njegovijem kao djelo od kamena safira i kao nebo kad je vedro.
Wọ́n sì rí Ọlọ́run Israẹli. Ní abẹ́ ẹsẹ̀ rẹ̀ ni ohun kan bí i pèpéle ti a fi òkúta safire ṣe wà. Èyí ti ó mọ́ nigínnigín bí àwọ̀ sánmọ̀ fúnra rẹ̀.
11 I ne pruži ruke svoje na izabrane izmeðu sinova Izrailjevih, nego vidješe Boga, pa jedoše i piše.
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kò gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè sí àwọn àgbàgbà Israẹli wọ̀nyí; wọ́n ri Ọlọ́run, wọ́n jẹ, wọ́n sì mu.
12 I reèe Gospod Mojsiju: popni se k meni na goru, i ostani ovdje, i daæu ti ploèe od kamena, zakon i zapovijesti, koje sam napisao, da ih uèiš.
Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Gòkè wá sí ọ̀dọ̀ mi, kí o sì dúró níhìn-ín. Èmi yóò sì fún ọ ní wàláà òkúta pẹ̀lú òfin àti ìlànà tí mo ti kọ sílẹ̀ fún ìtọ́sọ́nà wọn.”
13 Tada usta Mojsije s Isusom, koji ga služaše, i izaðe Mojsije na goru Božiju.
Nígbà náà ni Mose jáde lọ pẹ̀lú Joṣua arákùnrin rẹ̀. Mose lọ sí orí òkè Ọlọ́run.
14 A starješinama reèe: sjedite tu dok se vratimo k vama; a eto Aron i Or s vama; ko bi imao što, neka ide k njima.
Ó sì wí fún àwọn àgbàgbà pé, “Ẹ dúró dè wá níhìn-ín yìí, títí àwa yóò fi tún padà tọ̀ yín wá, sì kíyèsi i, Aaroni àti Huri ń bẹ pẹ̀lú yín, bí ẹnìkan bá ni ọ̀ràn kan, kí ó tọ̀ wọ́n lọ.”
15 I otide Mojsije na goru, a oblak pokri goru.
Nígbà tí Mose gun orí òkè lọ, ìkùùkuu bo orí òkè náà.
16 I bijaše slava Gospodnja na gori Sinajskoj, i oblak je pokrivaše šest dana; a u sedmi dan viknu Mojsija ispred oblaka.
Ògo Olúwa sì wà ní orí òkè Sinai. Ìkùùkuu bo orí òkè náà fún ọjọ́ mẹ́fà, ni ọjọ́ keje ni Olúwa kọ sí Mose láti inú ìkùùkuu náà wá.
17 I slava Gospodnja bješe po viðenju kao oganj koji sažiže na vrh gore pred sinovima Izrailjevim.
Ni ojú àwọn ọmọ Israẹli ògo Olúwa náà dàbí iná ajónirun ni orí òkè.
18 I Mojsije uðe usred oblaka, i pope se na goru; i osta Mojsije na gori èetrdeset dana i èetrdeset noæi.
Nígbà náà ni Mose wọ inú ìkùùkuu náà bí ó ti ń lọ ní orí òkè. Ó sì wà ni orí òkè náà ni ogójì ọ̀sán àti ogójì òru.

< Izlazak 24 >