< پْریرِتاح 28 >
اِتّھَں سَرْوّیشُ رَکْشاں پْراپْتیشُ تَتْرَتْیوپَدْوِیپَسْیَ نامَ مِلِیتیتِ تے جْناتَوَنْتَح۔ | 1 |
Nígbà tí gbogbo wa sì yọ tan ni àwa tó mọ̀ pé, Mẹlita ni a ń pè erékùṣù náà.
اَسَبھْیَلوکا یَتھیشْٹَمْ اَنُکَمْپاں کرِتْوا وَرْتَّمانَورِشْٹیح شِیتاچَّ وَہْنِں پْرَجّوالْیاسْماکَمْ آتِتھْیَمْ اَکُرْوَّنْ۔ | 2 |
Kì í ṣe oore díẹ̀ ni àwọn aláìgbédè náà ṣe fún wa. Nítorí ti wọ́n dáná, wọ́n sì gbà gbogbo wa sí ọ̀dọ̀ nítorí òjò ń rọ nígbà náà, àti nítorí òtútù.
کِنْتُ پَولَ اِنْدھَنانِ سَںگرِہْیَ یَدا تَسْمِنْ اَگْرَو نِرَکْشِپَتْ، تَدا وَہْنیح پْرَتاپاتْ ایکَح کرِشْنَسَرْپو نِرْگَتْیَ تَسْیَ ہَسْتے دْرَشْٹَوانْ۔ | 3 |
Nígbà tí Paulu sì ṣa ìdí ìṣẹ́pẹ́ igi jọ, ti ó sì kó o sínú iná, paramọ́lẹ̀ kan ti inú oru-iná jáde, ó di mọ́ ọn ní ọwọ́.
تےسَبھْیَلوکاسْتَسْیَ ہَسْتے سَرْپَمْ اَوَلَمْبَمانَں درِشْٹْوا پَرَسْپَرَمْ اُکْتَوَنْتَ ایشَ جَنووَشْیَں نَرَہا بھَوِشْیَتِ، یَتو یَدْیَپِ جَلَدھے رَکْشاں پْراپْتَوانْ تَتھاپِ پْرَتِپھَلَدایَکَ اینَں جِیوِتُں نَ دَداتِ۔ | 4 |
Bí àwọn aláìgbédè náà sì ti rí ẹranko olóró náà tí ó dì mọ́ ọn lọ́wọ́, wọ́n bá ara wọn sọ pé, “Dájúdájú apànìyàn ni ọkùnrin yìí, ẹni ti ó yọ nínú Òkun tan, ṣùgbọ́n tí ẹ̀san kò sì jẹ́ kí ó wà láààyè.”
کِنْتُ سَ ہَسْتَں وِدھُنْوَنْ تَں سَرْپَمْ اَگْنِمَدھْیے نِکْشِپْیَ کامَپِ پِیڈاں ناپْتَوانْ۔ | 5 |
Òun sì gbọn ẹranko náà sínú iná ohunkóhun kan kò sì ṣe é.
تَتو وِشَجْوالَیا ایتَسْیَ شَرِیرَں سْپھِیتَں بھَوِشْیَتِ یَدْوا ہَٹھادَیَں پْرانانْ تْیَکْشْیَتِیتِ نِشْچِتْیَ لوکا بَہُکْشَنانِ یاوَتْ تَدْ دْرَشْٹُں سْتھِتَوَنْتَح کِنْتُ تَسْیَ کَسْیاشْچِدْ وِپَدوگھَٹَناتْ تے تَدْوِپَرِیتَں وِجْنایَ بھاشِتَوَنْتَ ایشَ کَشْچِدْ دیوو بھَویتْ۔ | 6 |
Ṣùgbọ́n wọn ń wòye ìgbà tí yóò wù, tàbí tí yóò sì ṣubú lulẹ̀ láti kú lójijì; nígbà tí wọ́n wò títí, tí wọn kò sì rí nǹkan kan kí ó ṣe é, wọ́n pa èrò wọn dà pé, òrìṣà kan ni ọkùnrin yìí.
پُبْلِیَناما جَنَ ایکَسْتَسْیوپَدْوِیپَسْیادھِپَتِراسِیتْ تَتْرَ تَسْیَ بھُومْیادِ چَ سْتھِتَں۔ سَ جَنوسْمانْ نِجَگرِہَں نِیتْوا سَوجَنْیَں پْرَکاشْیَ دِنَتْرَیَں یاوَدْ اَسْماکَں آتِتھْیَمْ اَکَروتْ۔ | 7 |
Ní agbègbè ibẹ̀ ni ilé ọkùnrin ọlọ́lá erékùṣù náà wà, orúkọ ẹni tí a ń pè ní Pubiliu; ẹni tí ó ti ipa inú rere gbà wá sí ọ̀dọ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
تَدا تَسْیَ پُبْلِیَسْیَ پِتا جْوَراتِسارینَ پِیڈْیَمانَح سَنْ شَیّایامْ آسِیتْ؛ تَتَح پَولَسْتَسْیَ سَمِیپَں گَتْوا پْرارْتھَناں کرِتْوا تَسْیَ گاتْرے ہَسْتَں سَمَرْپْیَ تَں سْوَسْتھَں کرِتَوانْ۔ | 8 |
Ó sì ṣe, baba Pubiliu dùbúlẹ̀ àìsàn ibà àti ìgbẹ́-ọ̀rìn; ẹni tí Paulu wọlé tọ̀ lọ, tí ó sì gbàdúrà fún, nígbà tí ó sì fi ọwọ́ lé e, ó sì mú un láradá.
اِتّھَں بھُوتے تَدْوِیپَنِواسِنَ اِتَریپِ روگِلوکا آگَتْیَ نِرامَیا اَبھَوَنْ۔ | 9 |
Nígbà tí èyí sì ṣetán, àwọn ìyókù tí ó ni ààrùn ni erékùṣù náà tọ̀ ọ́ wá, ó sì mú wọn láradá.
تَسْماتّےسْماکَمْ اَتِیوَ سَتْکارَں کرِتَوَنْتَح، وِشیشَتَح پْرَسْتھانَسَمَیے پْرَیوجَنِییانِ نانَدْرَوْیانِ دَتَّوَنْتَح۔ | 10 |
Wọ́n sì bu ọlá púpọ̀ fún wa; nígbà tí a ń lọ, wọ́n sì fún wa ní ohun púpọ̀ tí a nílò ní ọ̀nà àjò wa.
اِتّھَں تَتْرَ تْرِشُ ماسیشُ گَتیشُ یَسْیَ چِہْنَں دِیَسْکُورِی تادرِشَ ایکَح سِکَنْدَرِییَنَگَرَسْیَ پوتَح شِیتَکالَں یاپَیَنْ تَسْمِنْ اُپَدْوِیپے تِشْٹھَتْ تَمیوَ پوتَں وَیَمْ آرُہْیَ یاتْرامْ اَکُرْمَّ۔ | 11 |
Lẹ́yìn oṣù mẹ́ta, a wọ ọkọ̀ ojú omi kan èyí tí ó lo àkókò òtútù ní erékùṣù náà. Ó jẹ́ ọkọ̀ ojú omi ti Alekisandiria, èyí tí àmì rẹ̀ jẹ́ tí òrìṣà ìbejì ti Kasitoru òun Polukisu.
تَتَح پْرَتھَمَتَح سُراکُوسَنَگَرَمْ اُپَسْتھایَ تَتْرَ تْرِینِ دِنانِ سْتھِتَوَنْتَح۔ | 12 |
Nígbà tí a sì gúnlẹ̀ ní Sirakusi, a gbé ibẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
تَسْمادْ آورِتْیَ رِیگِیَنَگَرَمْ اُپَسْتھِتاح دِنَیکَسْماتْ پَرَں دَکْشِنَوَیَو سانُکُولْیے سَتِ پَرَسْمِنْ دِوَسے پَتِیَلِینَگَرَمْ اُپاتِشْٹھامَ۔ | 13 |
Láti ibẹ̀ nígbà tí a lọ yíká; a dé Regiomu: nígbà tí ó sì di ọjọ́ kejì, afẹ́fẹ́ gúúsù bẹ̀rẹ̀ sí ní fẹ́, ní ọjọ́ kejì rẹ̀ a sì dé Puteoli.
تَتوسْماسُ تَتْرَتْیَں بھْراترِگَنَں پْراپْتیشُ تے سْوَیح سارْدّھَمْ اَسْمانْ سَپْتَ دِنانِ سْتھاپَیِتُمْ اَیَتَنْتَ، اِتّھَں وَیَں رومانَگَرَمْ پْرَتْیَگَچّھامَ۔ | 14 |
A sì rí àwọn arákùnrin kan níbẹ̀, tí wọ́n sì bẹ̀ wá láti bá wọn gbé fún ọjọ́ méje: bẹ́ẹ̀ ni a sì lọ sí ìhà Romu.
تَسْماتْ تَتْرَتْیاح بھْراتَروسْماکَمْ آگَمَنَوارْتّاں شْرُتْوا آپِّیَپھَرَں تْرِشْٹاوَرْنِینْچَ یاوَدْ اَگْریسَراح سَنْتوسْمانْ ساکْشاتْ کَرْتُّمْ آگَمَنْ؛ تیشاں دَرْشَناتْ پَولَ اِیشْوَرَں دھَنْیَں وَدَنْ آشْواسَمْ آپْتَوانْ۔ | 15 |
Àwọn arákùnrin ibẹ̀ gbúròó pé a ń bọ̀, wọ́n sì rìnrìn àjò títí wọ́n fi dé Apii Foroni àti sí ilé èrò mẹ́ta láti pàdé wa: nígbà tí Paulu sì rí wọn, ó dúpẹ́ lọ́wọ́ Ọlọ́run, ó sì mú ọkàn le.
اَسْماسُ رومانَگَرَں گَتیشُ شَتَسیناپَتِح سَرْوّانْ بَنْدِینْ پْرَدھانَسیناپَتیح سَمِیپے سَمارْپَیَتْ کِنْتُ پَولایَ سْوَرَکْشَکَپَداتِنا سَہَ پرِتھَگْ وَسْتُمْ اَنُمَتِں دَتَّوانْ۔ | 16 |
Nígbà tí a sì dé Romu, olórí àwọn ọmọ-ogun fi àwọn òǹdè lé olórí ẹ̀ṣọ́ lọ́wọ́, ṣùgbọ́n wọ́n gba Paulu láààyè láti máa dágbé fún ara rẹ̀ pẹ̀lú ọmọ-ogun tí ó ń ṣọ́ ọ.
دِنَتْرَیاتْ پَرَں پَولَسْتَدّیشَسْتھانْ پْرَدھانَیِہُودِنَ آہُوتَوانْ تَتَسْتیشُ سَمُپَسْتھِتیشُ سَ کَتھِتَوانْ، ہے بھْراترِگَنَ نِجَلوکاناں پُورْوَّپُرُشاناں وا رِیتے رْوِپَرِیتَں کِنْچَنَ کَرْمّاہَں ناکَرَوَں تَتھاپِ یِرُوشالَمَنِواسِنو لوکا ماں بَنْدِں کرِتْوا رومِلوکاناں ہَسْتیشُ سَمَرْپِتَوَنْتَح۔ | 17 |
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta, Paulu pe àwọn olórí Júù jọ. Nígbà tí wọ́n sì péjọ, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin ara, bí ó ti ṣe pé èmi kò ṣe ohun kan lòdì sí àwọn ènìyàn, tàbí sí àṣà àwọn baba wa, síbẹ̀ wọ́n fi mí lé àwọn ara Romu lọ́wọ́ ní òǹdè láti Jerusalẹmu wá.
رومِلوکا وِچارْیَّ مَمَ پْرانَہَنَنارْہَں کِمَپِ کارَنَں نَ پْراپْیَ ماں موچَیِتُمْ اَیچّھَنْ؛ | 18 |
Nígbà tí wọ́n sì wádìí ọ̀ràn mi, wọ́n fẹ́ jọ̀wọ́ mi lọ́wọ́ lọ, nítorí tí wọn kò rí ẹ̀sùn kan tí ó tọ́ sí ikú pẹ̀lú mi.
کِنْتُ یِہُودِلوکانامْ آپَتّیا مَیا کَیسَرَراجَسْیَ سَمِیپے وِچارَسْیَ پْرارْتھَنا کَرْتَّوْیا جاتا نوچیتْ نِجَدیشِییَلوکانْ پْرَتِ مَمَ کوپْیَبھِیوگو ناسْتِ۔ | 19 |
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn Júù sọ̀rọ̀ lòdì sí i, èyí sún mí láti fi ọ̀ràn náà lọ Kesari, kì í ṣe pe mo ní ẹ̀sùn kan láti fi kan àwọn ènìyàn mi.
ایتَتْکارَنادْ اَہَں یُشْمانْ دْرَشْٹُں سَںلَپِتُنْچاہُویَمْ اِسْراییلْوَشِییاناں پْرَتْیاشاہیتوہَمْ ایتینَ شُنْکھَلینَ بَدّھوبھَوَمْ۔ | 20 |
Ǹjẹ́ nítorí ọ̀ràn yìí ni mo ṣe ránṣẹ́ pè yín, láti rí yín àti láti bá yín sọ̀rọ̀ nítorí pé, nítorí ìrètí Israẹli ni a ṣe fi ẹ̀wọ̀n yìí dè mí.”
تَدا تے تَمْ اَوادِشُح، یِہُودِییَدیشادْ وَیَں تْوامَدھِ کِمَپِ پَتْرَں نَ پْراپْتا یے بھْراتَرَح سَمایاتاسْتیشاں کوپِ تَوَ کامَپِ وارْتّاں ناوَدَتْ اَبھَدْرَمَپِ ناکَتھَیَچَّ۔ | 21 |
Wọ́n sì wí fún un pé, “Àwa kò rí ìwé gbà láti Judea nítorí rẹ, bẹ́ẹ̀ ni ẹnìkan nínú àwọn arákùnrin tí ó ti ibẹ̀ wá kò ròyìn, tàbí kí ó sọ̀rọ̀ ibi kan sí ọ.
تَوَ مَتَں کِمِتِ وَیَں تْوَتَّح شْروتُمِچّھامَح۔ یَدْ اِدَں نَوِینَں مَتَمُتّھِتَں تَتْ سَرْوَّتْرَ سَرْوّیشاں نِکَٹے نِنْدِتَں جاتَمَ اِتِ وَیَں جانِیمَح۔ | 22 |
Ṣùgbọ́n àwa ń fẹ́ gbọ́ lẹ́nu rẹ ohun tí ìwọ rò nítorí bí ó ṣe ti ẹgbẹ́ ìlànà yìí ní, àwa mọ̀ pé, níbi gbogbo ni a ń sọ̀rọ̀ lòdì sí i.”
تَیسْتَدَرْتھَمْ ایکَسْمِنْ دِنے نِرُوپِتے تَسْمِنْ دِنے بَہَوَ ایکَتْرَ مِلِتْوا پَولَسْیَ واسَگرِہَمْ آگَچّھَنْ تَسْماتْ پَولَ آ پْراتَحکالاتْ سَنْدھْیاکالَں یاوَنْ مُوساوْیَوَسْتھاگْرَنْتھادْ بھَوِشْیَدْوادِناں گْرَنْتھیبھْیَشْچَ یِیشوح کَتھامْ اُتّھاپْیَ اِیشْوَرَسْیَ راجْیے پْرَمانَں دَتْوا تیشاں پْرَورِتِّں جَنَیِتُں چیشْٹِتَوانْ۔ | 23 |
Àwọn fi ẹnu kò lórí ọjọ́ tí wọn yóò ṣe ìpàdé pẹ̀lú Paulu, ọ̀pọ̀lọpọ̀ wọn ni ó tọ̀ ọ́ wa ni ilé àgbàwọ̀ rẹ̀; àwọn ẹni tí òun sọ àsọyé ọ̀rọ̀ ìjọba Ọlọ́run fún, ó ń yí wọn padà nípa ti Jesu láti inú òfin Mose àti àwọn wòlíì, láti òwúrọ̀ títí ó fi di àṣálẹ́.
کیچِتُّ تَسْیَ کَتھاں پْرَتْیایَنْ کیچِتُّ نَ پْرَتْیایَنْ؛ | 24 |
Àwọn ẹlòmíràn gba ohun tí ó wí gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni àwọn ẹlòmíràn kò sì gbà á gbọ́.
ایتَتْکارَناتْ تیشاں پَرَسْپَرَمْ اَنَیکْیاتْ سَرْوّے چَلِتَوَنْتَح؛ تَتھاپِ پَولَ ایتاں کَتھامیکاں کَتھِتَوانْ پَوِتْرَ آتْما یِشَیِیَسْیَ بھَوِشْیَدْوَکْتُ رْوَدَنادْ اَسْماکَں پِترِپُرُشیبھْیَ ایتاں کَتھاں بھَدْرَں کَتھَیاماسَ، یَتھا، | 25 |
Nígbà tí ohùn wọn kò ṣọ̀kan láàrín ara wọn, wọ́n túká, lẹ́yìn ìgbà tí Paulu sọ̀rọ̀ kan pé, “Ẹ̀mí Mímọ́ sọ òtítọ́ fún àwọn baba yín nígbà tí ó sọ láti ẹnu wòlíì Isaiah wí pé:
"اُپَگَتْیَ جَنانیتانْ تْوَں بھاشَسْوَ وَچَسْتْوِدَں۔ کَرْنَیح شْروشْیَتھَ یُویَں ہِ کِنْتُ یُویَں نَ بھوتْسْیَتھَ۔ نیتْرَے رْدْرَکْشْیَتھَ یُویَنْچَ جْناتُں یُویَں نَ شَکْشْیَتھَ۔ | 26 |
“‘Tọ àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ, kí ó sì wí pé, “Ní gbígbọ́ ẹ̀yin yóò gbọ́, kì yóò sì yé e yín; à ti ní rí rí ẹ̀yin yóò rí, ẹ̀yin kì yóò sí wòye.”
تے مانُشا یَتھا نیتْرَیح پَرِپَشْیَنْتِ نَیوَ ہِ۔ کَرْنَیح رْیَتھا نَ شرِنْوَنْتِ بُدھْیَنْتے نَ چَ مانَسَیح۔ وْیاوَرْتَّیَتْسُ چِتّانِ کالے کُتْراپِ تیشُ وَے۔ مَتَّسْتے مَنُجاح سْوَسْتھا یَتھا نَیوَ بھَوَنْتِ چَ۔ تَتھا تیشاں مَنُشْیاناں سَنْتِ سْتھُولا ہِ بُدّھَیَح۔ بَدھِرِیبھُوتَکَرْناشْچَ جاتاشْچَ مُدْرِتا درِشَح۔۔ | 27 |
Nítorí ti àyà àwọn ènìyàn yìí yigbì, etí wọn sì wúwo láti fi gbọ́, ojú wọn ni wọn sì ti di. Nítorí kí wọn má ba à fi ojú wọn rí, kí wọn kí ó má ba à fi etí wọn gbọ́, àti kí wọn má ba à fi ọkàn wọn mọ̀, kí wọn kí ó má ba à yípadà, àti kí èmi má ba à mú wọn láradá.’
اَتَ اِیشْوَرادْ یَتْ پَرِتْرانَں تَسْیَ وارْتّا بھِنَّدیشِییاناں سَمِیپَں پْریشِتا تَایوَ تاں گْرَہِیشْیَنْتِیتِ یُویَں جانِیتَ۔ | 28 |
“Ǹjẹ́ kí ẹ̀yin mọ́ èyí pé, a rán ìgbàlà Ọlọ́run sí àwọn kèfèrí wọ́n ó sì gbọ́!”
ایتادرِشْیاں کَتھایاں کَتھِتایاں سَتْیاں یِہُودِنَح پَرَسْپَرَں بَہُوِچارَں کُرْوَّنْتو گَتَوَنْتَح۔ | 29 |
اِتّھَں پَولَح سَمْپُورْنَں وَتْسَرَدْوَیَں یاوَدْ بھاٹَکِییے واسَگرِہے وَسَنْ یے لوکاسْتَسْیَ سَنِّدھِمْ آگَچّھَنْتِ تانْ سَرْوّانیوَ پَرِگرِہْلَنْ، | 30 |
Paulu sì gbé ilé àgbàwọ̀ rẹ̀ lọ́dún méjì gbáko, ó sì ń gbà gbogbo àwọn tí ó wọlé tọ̀ ọ́ wá.
نِرْوِگھْنَمْ اَتِشَیَنِحکْشوبھَمْ اِیشْوَرِییَراجَتْوَسْیَ کَتھاں پْرَچارَیَنْ پْرَبھَو یِیشَو کھْرِیشْٹے کَتھاح سَمُپادِشَتْ۔ اِتِ۔۔ | 31 |
Ó ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, ó ń fi ìgboyà kọ́ni ní àwọn ohun tí i ṣe ti Jesu Kristi Olúwa, ẹnìkan kò si dá a lẹ́kun.