< Mathayo 15 >

1 Na Amafarisayo na asimbi bhahenzele wha Yesu afume Huyerusalemu. Na yanje,
Nígbà náà ní àwọn Farisi àti àwọn olùkọ́ òfin tọ Jesu wá láti Jerusalẹmu,
2 “Yenu abhanafunzi bhananganya amalisizi gazehe? Afwatanaje sagabhanawa inyobhe zyawo lwabhalya ishalye.”
wọn béèrè pé, “Èéṣe tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ fi ń rú òfin àtayébáyé àwọn alàgbà? Nítorí tí wọn kò wẹ ọwọ́ wọn kí wọ́n tó jẹun!”
3 U Yesu abhajibu nahubhawozya, “Namwe yenu munanganya indajizyo ya Gosi kwa ajili yamalisizi genyu?
Jesu sì dá wọn lóhùn pé, “Èéha ṣe tí ẹ̀yin fi rú òfin Ọlọ́run, nítorí àṣà yín?
4 Afwatanaje o Ngolobhi ayanjile, 'Ubheninshinshi wha baba waho nu maye waho; na 'Wayanga imbibhi wha baba wakwe na whamaye wakwe, na hakika afwe.'
Nítorí Ọlọ́run wí pé, ‘Bọ̀wọ̀ fún Baba òun ìyá rẹ,’ àti pé, ‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ọ̀rọ̀-òdì sí baba tàbí ìyá rẹ̀, ní láti kú.’
5 Ila amwe muyanga, na wahumozya ubaba wakwe nu maye wakwe, “Kila ulwavwe ambalo andapatile afume huline eshe mpesya afume wha Ngolobhi,”
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin wí pé, ẹnikẹ́ni tí ó bá wí fún baba tàbí ìyá rẹ̀ pé, ‘Ẹ̀bùn fún Ọlọ́run ni ohunkóhun tí ìwọ ìbá fi jèrè lára mi,’
6 “Umuntu oyo sagaalinihaja yabheninshinshi wha baba wakwe. Katika inamuna ene mubadilisizye izulya Ngolobhi kwa ajili yimalisizi genyu.
tí Òun kò sì bọ̀wọ̀ fún baba tàbí ìyá rẹ̀, ó bọ́; bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin sọ òfin Ọlọ́run di asán nípa àṣà yín.
7 Amwe bhanafiki, shinza hansi u Isaya shakuwilwe pamwanya yenyu shayanjile,
Ẹ̀yin àgàbàgebè, ní òtítọ́ ni Wòlíì Isaiah sọtẹ́lẹ̀ nípa yín wí pé:
8 'Abhantu ebha bhahwfpanyila inshinshi ane humalomu gawo, ila amioyo gawo galihutali nane.
“‘Àwọn ènìyàn wọ̀nyí ń fi ẹnu lásán bu ọlá fún mi, ṣùgbọ́n ọkàn wọn jìnnà réré sí mi.
9 Bhahunsaya wene, kwa sababu bhafundizya amamanyizyo agali malajizyo gabhanadamu.”
Lásán ni ìsìn wọn; nítorí pé wọ́n ń fi òfin ènìyàn kọ́ ni ní ẹ̀kọ́.’”
10 Epo abhakwizizye ikusanyiho na hubhawozye, “Tejelezi na mumanye
Jesu pe ọ̀pọ̀ ènìyàn wá sí ọ̀dọ̀ rẹ, ó wí pé, “Ẹ tẹ́tí, ẹ sì jẹ́ kí nǹkan tí mo sọ yé yín.
11 Nahamo ahantu hahahinjila mwilomu lya muntu nahumombe ubhibhi. Ila, shila shishifuma mwilomu eshi shesho shimomba umuntu abhe mibhi.”
Ènìyàn kò di aláìmọ́ nípa ohun tí ó wọ ẹnu ènìyàn, ṣùgbọ́n èyí tí ó ti ẹnu jáde wá ni ó sọ ní di aláìmọ́.”
12 Epo abhanafunzi bhamalila nayanje nu Yesu, “Eshi!, Uwhele Amafarisayo lwabhalyevwa lila izu bhavisiwilwe?”
Nígbà náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ tọ̀ ọ́ wá, wọ́n wí fún un pé, “Ǹjẹ́ ìwọ mọ̀ pé inú bí àwọn Farisi lẹ́yìn tí wọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó sọ yìí?”
13 U Yesu abhajibu na yanje, “Kila likwi lwasagatotile ubaba wane wahumwanya lyayisenywa.
Jesu dá wọn lóhùn pé, “Gbogbo igi tí Baba mi ti ń bẹ ni ọ̀run kò bá gbìn ni á ó fàtu tigbòǹgbò tigbòǹgbò,
14 Bhaleshi bhene, abhene bhalongozi bhivipofu. Hansi umuntu shipofu abhahunongozye ushipofu uwamwawo, wonti bhabhele bhanzagwe mwilende.”
ẹ fi wọ́n sílẹ̀; afọ́jú tí ń fi ọ̀nà han afọ́jú ni wọ́n. Bí afọ́jú bá sì ń fi ọ̀nà han afọ́jú, àwọn méjèèjì ni yóò jìn sí kòtò.”
15 Upetro ajibu na humozye u Yesu, “Tiwozye umfano ogu hulite,
Peteru wí, “Ṣe àlàyé òwe yìí fún wa.”
16 U Yesu ajibu, “Namwe bado sagamuhelewa?
Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Èéha ṣe tí ìwọ fi jẹ́ aláìmòye síbẹ̀”?
17 Namwe sagamuwhenya aje shila shishi bhala mwilomu shishilila muvyanda na bhale muchoho?
“Ẹyin kò mọ̀ pé ohunkóhun tí ó gba ẹnu wọlé, yóò gba ti ọ̀nà oúnjẹ lọ, a yóò sì yà á jáde?
18 Ila ivintu vyonti vivifuma mwilomu vifuma mhati yimoyo. Shesho ivintu vihumeha umuntu ubhibhi.
Ṣùgbọ́n ohun tí a ń sọ jáde láti ẹnu, inú ọkàn ni ó ti ń wá, èyí sì ni ó ń sọ ènìyàn di aláìmọ́.
19 Afwatanaje katika umoyo gafuma amawazo amabhibhi, ugoji, uumalaya, uashelati, uwibha, uashuda wilenga ni ndigo.
Ṣùgbọ́n láti ọkàn ni èrò búburú ti wá, bí ìpànìyàn, panṣágà, àgbèrè, olè jíjà, irọ́ àti ọ̀rọ̀ ìbàjẹ́.
20 Ega gamambo gahumeha umuntu ubhibhi. Ila alye bila anawe inyobhe sagahuumomba umuntu abhe mibhi.”
Àwọn tí a dárúkọ wọ̀nyí ni ó ń sọ ènìyàn di aláìmọ́. Ṣùgbọ́n láti jẹun láì wẹ ọwọ́, kò lè sọ ènìyàn di aláìmọ́.”
21 Epo u Yesu ayepa isehemu ela nahujisegusye aeleshela uhupande wi miji gi Tiro ni Sidoni.
Jesu sì ti ibẹ̀ kúrò lọ sí Tire àti Sidoni.
22 Enya ayenza onshe Umkanani afume uwupande owo. Azuvya isauti ayanga, “Ndolele inkombo, Gosi, Mwana wa Daudi; umwale wane ayemba hani ni mpepo.”
Obìnrin kan láti Kenaani, tí ó ń gbé ibẹ̀ wá sí ọ̀dọ̀ rẹ̀. Ó ń bẹ̀bẹ̀, ó sì kígbe pé, “Olúwa, ọmọ Dafidi, ṣàánú fún mi; ọmọbìnrin mi ní ẹ̀mí èṣù ti ń dá a lóró gidigidi.”
23 Ila u Yesu sagaajibule izu. Abhanafunzi bhakwe bhenza bhanabha bhayanga, “Mwefwe abhaje ulwakwe, maana ahutikhomela ihalanga.”
Ṣùgbọ́n Jesu kò fún un ní ìdáhùn, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sì gbà á níyànjú pé, “Lé obìnrin náà lọ, nítorí ó ń kígbe tọ̀ wá lẹ́yìn.”
24 U Yesu abhajibule nayanje, Saganatumwile wha muntu wowonti ila whingole zizitejile zinyumba yi Israeli.”
Ó dáhùn pé, “Àgùntàn ilẹ̀ Israẹli tí ó nù nìkan ni a rán mi sí.”
25 Ila ahenzele na whiname whilongolela lyakwe, ayanga, “Gosi navwe.”
Obìnrin náà wá, ó wólẹ̀ níwájú rẹ̀, ó bẹ̀bẹ̀ sí i pé, “Olúwa ṣàánú fún mi.”
26 Ajibule na yanje, “Sagashinza awheje ishalye shabhana na huzitajile embwa.”
Ó sì dáhùn wí pé, “Kò tọ́ kí a gbé oúnjẹ àwọn ọmọ fún àwọn ajá.”
27 Ayanga, “Eshi, Gosi, hata esho embwa indodo zilya ishalye shishigwa pameza pa Gosi wawo.”
Obìnrin náà sì wí pé, “Bẹ́ẹ̀ ni, síbẹ̀síbẹ̀ àwọn ajá a máa jẹ èrúnrún tí ó ti orí tábìlì olówó wọn bọ́ sílẹ̀.”
28 Epo u Yesu ajibu na yanje “Anshe, ulweteho lwaho gosi.” Na ifanyishe huliwe hansi shuwhanza.” Nu mwale wakwe ali aponile husala yeyo.
Jesu sì sọ fún obìnrin náà pé, “Ìgbàgbọ́ ńlá ni tìrẹ! A sì ti dáhùn ìbéèrè rẹ.” A sì mú ọmọbìnrin rẹ̀ láradá ní wákàtí kan náà.
29 U Yesu asogoye isehemu ela nabhale karibu ni bahari yi Galilaya. Tena abhala humwanya yigamba na khale oho.
Jesu ti ibẹ̀ lọ sí Òkun Galili. Ó gun orí òkè, o sì jókòó níbẹ̀.
30 Empoga ingosi yahenza hukwakwe. Na hunetele bhasaga bhajenda avipofu, abubu, bhishilema na bhanje vinji, bhabhali bhabhinile. Bhabhabheshele pamanama ga Yesu abhaponyla.
Ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn sì tọ̀ ọ́ wá, àti àwọn arọ, afọ́jú, amúnkùn ún, odi àti ọ̀pọ̀ àwọn aláìsàn mìíràn. Wọ́n gbé wọn kalẹ̀ lẹ́sẹ̀ Jesu. Òun sì mú gbogbo wọn láradá.
31 Na bhene empoga bhaswijile lwabhalolile amabubu bhayanga, ni vilema bhabhewha womi, aviwete bhajenda, nivipofu bhalola. Bhatemele Ongolobhi wi Israeli.
Ẹnu ya ọ̀pọ̀ ènìyàn nígbà tí wọ́n rí àwọn odi tó ń sọ̀rọ̀, amúnkùn ún tó di alára pípé, arọ tí ó ń rìn àti àwọn afọ́jú tí ó ríran. Wọ́n sì ń fi ìyìn fún Ọlọ́run Israẹli.
32 U Yesu abhakwizizye abhanafunzi bhakwe nayanje, “Imbaloleye inkombo impoga, husababu bhali nane hinsiku zitatu bila alye ahantu hohonti, sigimbahubhalaje bhabhale humwawo bila alye, bhasa hazimile mwidala.”
Jesu pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ sọ́dọ̀, ó wí pé, “Àánú àwọn ènìyàn wọ̀nyí ṣe mí; nítorí wọ́n ti wà níhìn-ín pẹ̀lú mi fún ọjọ́ mẹ́ta gbáko báyìí. Wọn kò sì tún ní oúnjẹ mọ́. Èmi kò fẹ́ kí wọn padà lébi, nítorí òyì lè kọ́ wọn lójú ọ̀nà.”
33 Abhanafunzi bhakwe bhamozya, “Tibhawezye apate amabumunda gatosye epa pinyiha awhigutizye empoga ingosi eshi?”
Àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sì dá a lóhùn pé, “Níbo ni àwa yóò ti rí oúnjẹ ní ijù níhìn-ín yìí láti fi bọ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn yìí?”
34 U Yesu abhawozya, “Muli na mabumunda galenga?” Bhayanga, “Saba, neswe indodo ndodo.”
Jesu sì béèrè pé, “Ìṣù àkàrà mélòó ni ẹ̀yin ní?” Wọ́n sì dáhùn pé, “Àwa ní ìṣù àkàrà méje pẹ̀lú àwọn ẹja wẹ́wẹ́ díẹ̀.”
35 U Yesu ayiwozya empoga ikhale pansi.
Jesu sì sọ fún gbogbo ènìyàn kí wọn jókòó lórí ilẹ̀.
36 Ahejile gala amabumunda saba neswe, na baada ya husalifwe, agamensula na hubhapele abhanafunzi. Abhanafunzi bhabhapela empoga.
Òun sì mú ìṣù àkàrà méje náà àti ẹja náà. Ó sì fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run, ó bù wọ́n sì wẹ́wẹ́, ó sì fi wọ́n fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀. Wọ́n sì pín in fún àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn náà.
37 Abhantu bhonti bhalya natosewe. Bwawonganya gagasyalile ivipande vivyalye vya vyasageye vipande vipande, vyamemile iviseje saba.
Gbogbo wọn jẹ, wọ́n sì yó. Lẹ́yìn náà, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sì ṣa èyí tókù, ẹ̀kún agbọ̀n méje ni èyí tó ṣẹ́kù jẹ́.
38 Wonti bhabhaliye bhali alume elfu zene bila abhashe na bhana.
Gbogbo wọn sì jẹ́ ẹgbàajì ọkùnrin láì kan àwọn obìnrin àti ọmọdé.
39 Tena u Yesu alaga empoga bhabha bhewo na ayinjila mkasi yi mashua na bhale isehemu zi Magadani.
Lẹ́yìn náà, Jesu rán àwọn ènìyàn náà lọ sí ilé wọn, ó sì bọ́ sínú ọkọ̀, ó rékọjá lọ sí ẹkùn Magadani.

< Mathayo 15 >