< Luka 17 >
1 Wabhabhola asambelezewa bhakwe, “evisyo sevi nebudi ahwenze lelo ole wakwe omntu ola ambaye gahwenza afwatane nomwahale!
Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Kò le ṣe kí ohun ìkọ̀sẹ̀ máa wa, ṣùgbọ́n ègbé ni fún ẹni tí ó ti ipasẹ̀ rẹ̀ dé.
2 Yakhondeye zaidi omntu oyo iwe elyasyole lipinyeve msingo yakwe aponywe mwidimi, ashile abhavisye miongoni mwadodo ebha.
Ìbá sàn fún un kí a so ọlọ mọ́ ọn ní ọrùn, kí a sì gbé e jù sínú Òkun, ju kí ó mú ọ̀kan nínú àwọn kékeré wọ̀nyí kọsẹ̀.
3 Hwirindi. Nkashile ohoro waho nkakoseye sunde, nkarambe sajire.
Ẹ máa kíyèsára yín. “Bí arákùnrin rẹ bá ṣẹ̀, bá a wí; bí ó bá sì ronúpìwàdà, dáríjì ín.
4 Nankashile akosire mara saba katika isiku limo, nawele hwiliwe mara saba nkayanje, 'erabha,' sajire!”
Bí ó bá sì ṣẹ̀ ọ́ ní igba méje ní òòjọ́, tí ó padà tọ̀ ọ́ wá ní ìgbà méje ní òòjọ́ pé, ‘Mo ronúpìwàdà,’ dáríjì ín.”
5 Atumwa bhabhola Gosi, “Tonjezye oweteho.”
Àwọn aposteli sì wí fún Olúwa pé, “Bù sí ìgbàgbọ́ wa.”
6 Ogosi wayanga, “nkashele mgari no lweteho ekiasi eshe chembe eye haradali, mwezaga alibhole iko eli senyeha, 'utotwe mwidimi,' wope ungewaheshimu.
Olúwa sì wí pé, “Bí ẹ̀yin bá ní ìgbàgbọ́ bí hóró irúgbìn musitadi, ẹ̀yin yóò lè wí fún igi sikamine yìí pé, ‘Di fi fà á tu, kí a sì gbìn ọ́ sínú Òkun,’ yóò sì gbọ́ tiyín.
7 Lelo wenu hwilimwe, omwanesho obhomba yalima au yadima ing'ombe, yabhalubho nawera afume hugonda, 'Enzaa epa nanali khara olye eshalye?
“Ṣùgbọ́n ta ni nínú yín, tí ó ní ọmọ ọ̀dọ̀, tí ó ń tulẹ̀, tàbí tí ó ń bọ́ ẹran, tí yóò wí fún un lójúkan náà tí ó bá ti oko dé pé, ‘Lọ í jókòó láti jẹun’?
8 Je sabhahulobhe mbombele tayari eshalye endwe, hwipinye ombombele hata endwe na mwele. Nawe pobhalya na mwele?
Tí kì yóò kúkú wí fún un pé, ‘Pèsè ohun tí èmi yóò jẹ, sì di àmùrè, kí ìwọ kí ó máa ṣe ìránṣẹ́ fún mi, títí èmi ó fi jẹ kí èmi ó sì mu tán; lẹ́yìn náà ni ìwọ ó sì jẹ, tí ìwọ ó sì mu’?
9 Je abhahupere emwasalipa ola obhomba mbombo afwanaje abhombile galajiziwe?
Òun ó ha máa dá ọpẹ́ lọ́wọ́ ọmọ ọ̀dọ̀ náà, nítorí ó ṣe ohun tí a pàṣẹ fún un bí? Èmi kò rò bẹ́ẹ̀.
10 Shesho namwe namwayibha mumari abhombe gonti gamlajiziwe yangaje 'Ate tili bhasontezewa bhasebhali ne faida. Tibhombile wene gaganziwaga tibhombe.'
Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin pẹ̀lú, nígbà tí ẹ bá ti ṣe ohun gbogbo tí a pàṣẹ fún yín tán, ẹ wí pé, ‘Aláìlérè ọmọ ọ̀dọ̀ ni wá: èyí tí í ṣe iṣẹ́ wa láti ṣe, ní àwa ti ṣe.’”
11 Yabha nabhali mwidara nabhala hu Yerusalemu, ali ashira mhati eye Samaria na Galilaya.
Ó sì ṣe, bí ó ti ń lọ sí Jerusalẹmu, ó kọjá láàrín Samaria Galili.
12 Nawinjira mshijiji shimo, atangene nu bhantu kumi bhali no ukoma. Bhemelela sahutari
Bí ó sì ti ń wọ inú ìletò kan lọ, àwọn ọkùnrin adẹ́tẹ̀ mẹ́wàá pàdé rẹ̀, wọ́n dúró ní òkèrè,
13 bhakhora humaza bhayanga “Ee Yesu, Gosi owa Gosi otisajire.”
wọ́n sì kígbe sókè wí pé, “Jesu, Olùkọ́, ṣàánú fún wa.”
14 Nawabhalola wabhabhola, “Eshi bhalaji mhwibhonezye hwa kohani.” yabha nabhali bhabhale bhahozyewe.
Nígbà tí ó rí wọn, ó wí fún wọn pé, “Ẹ lọ í fi ara yín hàn fún àwọn àlùfáà.” Ó sì ṣe, bí wọ́n ti ń lọ, wọ́n sì di mímọ́.
15 Na omo miongoni mwabho nawalola aje aponile awelile, ohuu ahutukuzya Ongolobhe hwizu igosi.
Nígbà tí ọ̀kan nínú wọn rí i pé a mú òun láradá ó padà, ó sì fi ohùn rara yin Ọlọ́run lógo.
16 Wagwa fugamila pamagaga gakwe na husalifwe wapa ali msamaria.
Ó sì wólẹ̀ lẹ́bàá ẹsẹ̀ rẹ̀, ó ń dúpẹ́ ní ọwọ́ rẹ̀: ará Samaria ni òun í ṣe.
17 O Yesu wagalura, wayanga, “Sebhatakasyewe wonti kumi? Bhala tisa bhalihwi?
Jesu sì dáhùn wí pé, “Àwọn mẹ́wàá kí a sọ di mímọ́? Àwọn mẹ́sàn-án ìyókù ha dà?
18 Eshi sebhabhonesha bhabhawelile hupele Ongolobhe, outukufu ila ojenyi ono?”
A kò rí ẹnìkan tí ó padà wá fi ògo fún Ọlọ́run, bí kò ṣe àlejò yìí?”
19 Wabhora, “Imelela walaga wewe olweteho lwaho lumwauye.”
Ó sì wí fún un pé, “Dìde, kí o sì máa lọ, ìgbàgbọ́ rẹ mú ọ láradá.”
20 Nabhozyewaga na mafarisayo umwene owa Ngolobhe wayenza ndii, Aglula wabhabhola, “Umwe owa Ngolobhe seuhwenza agodezyegozye.
Nígbà tí àwọn Farisi bi í pé, nígbà wo ni ìjọba Ọlọ́run yóò dé, ó dá wọn lóhùn pé, “Ìjọba Ọlọ́run kì í wá pẹ̀lú àmì.
21 Wala sebhayiyanga, 'Enya uhweli ohwo!' au, 'Hula!' afwanaje enya umwene owa Ngolobhe uhweli mhati yenyu.”
Bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò wí pé, ‘Kíyèsi i níhìn-ín!’ tàbí ‘Kíyèsi i lọ́hùn ún ni!’ sá à wò ó, ìjọba Ọlọ́run ń bẹ nínú yín.”
22 Wabhabhola asambeleziwa bhakwe, “Ensiku zihwenza namwitamani alole isiku limo katika ensiku zyakwe Omwana wa Adamu, samwaizilola.
Ó sì wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ọjọ́ ń bọ̀, nígbà tí ẹ̀yin yóò fẹ́ láti rí ọ̀kan nínú ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn, ẹ̀yin kì yóò sì rí i.
23 Antele bhayibhabhola, 'Enyi, ohu! Mganje, sogole pala!' Paruhweli wala msabharondozye,
Wọ́n sì wí fún yín pé, ‘Wò ó níhìn-ín!’ tàbí ‘Wò ó lọ́hùn ún!’ Ẹ máa lọ, ẹ má ṣe tẹ̀lé wọn.
24 afwanaje neshe shila oumeme shaukhozya hata upande ou owensi eye mwanya. Esho shashayiha Omwana owa Adamu katika ensiku zyakwe.
Nítorí gẹ́gẹ́ bí mọ̀nàmọ́ná ti í kọ ní apá kan lábẹ́ ọ̀run, tí sì í mọ́lẹ̀ ní apá kejì lábẹ́ ọ̀run, bẹ́ẹ̀ ni Ọmọ Ènìyàn yóò sì rí ní ọjọ́ rẹ̀.
25 Lelo ahwanda sali nebudi apate marabha aminji na khanwe neshikholo.
Ṣùgbọ́n kò lè ṣàìmá kọ́ jìyà ohun púpọ̀, kí a sì kọ̀ ọ́ lọ́dọ̀ ìran yìí.
26 Ila nkashele shashahali ensiku ezya Nuhu, esho shashayibha katika ensiku zyakwe Omwana owa Adamu.
“Bí ó ti rí ní ọjọ́ Noa, bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ Ọmọ Ènìyàn.
27 Bhali bhalya na mwele na hweje na hwegwe hata isiku ila o Nuhu yahinjile katika mwisafina amakhoshi gahishile gabhangamizizye wonti.
Wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń gbéyàwó, wọ́n sì ń fa ìyàwó fún ni, títí ó fi di ọjọ́ ti Noa wọ inú ọkọ̀ lọ, kíkún omi sì dé, ó sì run gbogbo wọn.
28 Na nkashile shahali katika ensiku zya Lutu, bhali bhalya na mwele, wali bhakala na kazye, bhatotaga nazenje.
“Bí ó sì ti rí ní ọjọ́ Lọti; wọ́n ń jẹ, wọ́n ń mu, wọ́n ń rà, wọ́n ń tà, wọ́n ń gbìn, wọ́n ń kọ́lé,
29 Lelo isiku lila Lutu yafumile Msodoma, gwahishile omwoto neshibiriti afume amwanya gwabhatezizye wonti.
ṣùgbọ́n ní ọjọ́ náà tí Lọti jáde kúrò ní Sodomu, òjò iná àti sulfuru rọ̀ láti ọ̀run wá, ó sì run gbogbo wọn.
30 Esho shashayibha isiku lila lyayibhonesyewa owa Omwana owa Adamu.
“Gẹ́gẹ́ bẹ́ẹ̀ ni yóò rí ní ọjọ́ náà tí Ọmọ Ènìyàn yóò farahàn.
31 Katika isiku lila yali juu yogoro na evyelelo vyakuwa vili mhati eyenyumba agaje hwishe ili ayeje. Nantele yali hugonda ga jewele hwisalo.
Ní ọjọ́ náà, ẹni tí ó bá wà lórí ilé, tí ẹrù rẹ̀ sì ń bẹ ní ilẹ̀, kí ó má ṣe sọ̀kalẹ̀ láti wá kó o; ẹni tí ó bá sì wà ní oko, kí ó má ṣe padà sẹ́yìn.
33 Omntu yoyonti yabhaponje enafisi yakwe abhayitezye nayoyonti yayitezye, abhayiponie.
Ẹnikẹ́ni tí ó bá ń wá àti gba ẹ̀mí rẹ̀ là yóò sọ ọ́ nù; ẹnikẹ́ni tí ó bá sì sọ ọ́ nù yóò gbà á là.
34 Wabhabhola, osiku owo abhantu bhabhele bhayibha ishitara shimo. Omo ayegwe omo ayilehwa.
Mo wí fún yín, ní òru ọjọ́ náà, ènìyàn méjì yóò wà lórí àkéte kan; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.
35 Abhashe bhabhele bhayibha bhasya pandwemo, omo ayegwe omo ayilehwa.” Abhantu bhabheke bhayibha hugonda omo ayegwa omo ayirehwa.”
Ènìyàn méjì yóò sì máa lọ ọlọ pọ̀; a ó mú ọ̀kan, a ó sì fi èkejì sílẹ̀.”
37 Bhagalula bhabhozya, “Woshi, Gosi?” Wabhabhola, “Peli efwe nyene pepo pabhayitanganila enyonyi.”
Wọ́n sì dá a lóhùn, wọ́n bi í pé, “Níbo, Olúwa?” Ó sì wí fún wọn pé, “Níbi tí òkú bá gbé wà, níbẹ̀ pẹ̀lú ni igún ìkójọpọ̀ sí.”