< МАЛЕАХИ 4 >
1 „Кэч ятэ, вине зиуа каре ва арде ка ун куптор! Тоць чей труфашь ши тоць чей рэй вор фи ка мириштя; зиуа каре вине ый ва арде”, зиче Домнул оштирилор, „ши ну ле ва лэса нич рэдэчинэ, нич рамурэ.
“Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; tí yóò máa jó bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà tí ń bọ̀ yóò si jó wọn run,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Ti ki yóò fi kù gbòǹgbò kan tàbí ẹ̀ka kan fún wọn.
2 Дар пентру вой, каре вэ темець де Нумеле Меу, ва рэсэри Соареле неприхэнирий ши тэмэдуиря ва фи суб арипиле Луй; вець еши ши вець сэри ка вицеий дин гражд.
Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀lú ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. Ẹ̀yin yóò sì jáde lọ, ẹ̀yin yóò sì máa fò fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù tí a tú sílẹ̀ lórí ìso.
3 Ши вець кэлка ын пичоаре пе чей рэй, кэч ей вор фи ка ченуша суб талпа пичоарелор воастре ын зиуа пе каре о прегэтеск Еу”, зиче Домнул оштирилор.
Ẹ̀yin yóò sì tẹ àwọn ènìyàn búburú mọ́lẹ̀: nítorí wọn yóò di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ náà tí èmi yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
4 „Адучеци-вэ аминте де Леӂя луй Мойсе, робул Меу, кэруя й-ам дат ын Хореб рындуель ши порунчь пентру тот Исраелул!
“Ẹ rántí òfin Mose ìránṣẹ́ mi, àwọn ìlànà àti òfin èyí tí mo fún un ní Horebu fún gbogbo Israẹli.”
5 Ятэ, вэ вой тримите пе пророкул Илие ынаинте де а вени зиуа Домнулуй, зиуа ачея маре ши ынфрикошатэ.
“Wò ó, èmi yóò rán wòlíì Elijah sí i yín, ki ọjọ́ ńlá, ọjọ́ ẹ̀rù Olúwa to dé.
6 Ел ва ынтоарче инима пэринцилор спре копий ши инима копиилор спре пэринций лор, ка ну кумва, ла вениря Мя, сэ ловеск цара ку блестем!”
Òun yóò sì pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ọkàn àwọn ọmọ sì ti àwọn baba wọn, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò wá, èmi yóò sì fi ilẹ̀ náà gégùn.”