< Neemia 2 >

1 Și s-a întâmplat în luna Nisan, în anul al douăzecilea al împăratului Artaxerxes, că era vin înaintea lui; și am luat vinul și l-am dat împăratului. Și, nu fusesem mai înainte trist în prezența lui.
Ní oṣù Nisani, ní ogún ọdún ìjọba ọba Artasasta, nígbà tí a gbé wáìnì wá fún un, mo gbé wáìnì náà, mo fi fún ọba, ìbànújẹ́ kò hàn ní ojú mi rí ní iwájú rẹ̀.
2 De aceea împăratul mi-a spus: De ce este înfățișarea ta tristă, văzând că nu ești bolnav? Aceasta nu este nimic altceva decât tristețe a inimii. Atunci m-am înfricoșat foarte tare,
Nítorí náà ni ọba béèrè lọ́wọ́ mi pé, “Èéṣe tí ojú rẹ fi fàro nígbà tí kò rẹ̀ ọ́? Èyí kì í ṣe ohun mìíràn bí kò ṣe ìbànújẹ́ ọkàn.” Ẹ̀rù bà mí gidigidi,
3 Și am spus împăratului: Veșnic să trăiască împăratul, de ce să nu fie înfățișarea mea tristă, când cetatea, locul mormintelor părinților mei, șade risipită și porțile ei au fost mistuite de foc?
ṣùgbọ́n mo wí fún ọba pé, “Kí ọba kí ó pẹ́! Èéṣe tí ojú mi ko ṣe ní fàro, nígbà tí ìlú tí a sin àwọn baba mi sí wà ní ahoro, tí a sì ti fi iná run àwọn ibodè rẹ̀?”
4 Atunci împăratul mi-a spus: Ce cauți? Astfel, m-am rugat Dumnezeului cerului.
Ọba wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ ń fẹ́?” Nígbà náà, ni mo gbàdúrà sí Ọlọ́run ọ̀run,
5 Și am spus împăratului: Dacă place împăratului și dacă servitorul tău ar găsi favoare înaintea feței tale, să mă trimiți în Iuda, la cetatea mormintelor părinților mei, să o construiesc.
mo sì dá ọba lóhùn pé, “Ti ó bá wu ọba, tí ìránṣẹ́ rẹ bá sì rí ojúrere ní ojú rẹ, jẹ́ kí ó rán mi lọ sí ìlú náà ní Juda níbi tí a sin àwọn baba mi nítorí kí èmi lè tún un kọ́.”
6 Și împăratul mi-a spus (împărăteasa de asemenea ședea lângă el): Cât de lungă va fi călătoria ta? Și când te vei întoarce? Astfel a făcut plăcere împăratului să mă trimită; și i-am hotărât un timp.
Nígbà náà ni ọba, pẹ̀lú ìyàwó rẹ̀ tí ó jókòó lẹ́gbẹ̀ẹ́ rẹ̀, bi mí pé, “Báwo ni ìrìnàjò náà yóò ṣe pẹ́ ọ tó, nígbà wo sì ni ìwọ yóò padà?” Ó dùn mọ́ ọba láti rán mi lọ, bẹ́ẹ̀ ni mo dá àkókò kan.
7 Mai mult, am spus împăratului: Dacă ar place împăratului, să mi se dea scrisori către guvernatorii de dincolo de râu, ca să mă lase să trec până voi ajunge în Iuda;
Mo sì tún wí fún ọba pé, “Bí ó bá wu ọba, kí ó fún mi ní lẹ́tà sí àwọn baálẹ̀ òkè odò Eufurate kí wọ́n le mú mi kọjá títí èmi yóò fi dé Juda láìléwu.
8 Și o scrisoare către Asaf păzitorul pădurii împăratului, ca să îmi dea lemnăria să fac bârne pentru porțile palatului care aparținea de casă, și pentru zidul cetății și pentru casa în care voi intra. Și împăratul mi-a dat, conform cu mâna cea bună a Dumnezeului meu peste mine.
Kí èmi sì gba lẹ́tà kan lọ́wọ́ fún Asafu, olùṣọ́ igbó ọba, nítorí kí ó lè fún mi ní igi láti fi ṣe àtẹ́rígbà fún ibodè ilé ìṣọ́ tẹmpili àti fún odi ìlú náà àti fún ilé tí èmi yóò gbé?” Nítorí ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi wà lórí mi, ọba fi ìbéèrè mi fún mi.
9 Atunci am mers la guvernatorii de dincolo de râu și le-am dat scrisorile împăratului. Și împăratul trimisese căpetenii ale armatei și călăreți cu mine.
Bẹ́ẹ̀ ni mo lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn baálẹ̀ agbègbè Eufurate, mo sì fún wọn ní àwọn lẹ́tà ọba. Ọba sì ti rán àwọn ológun àti àwọn ẹlẹ́ṣin ogun pẹ̀lú mi.
10 Când Sanbalat horonitul și Tobia, servitorul, amonitul, au auzit de aceasta, i-a mâhnit foarte tare că a venit un om să caute bunăstarea copiilor lui Israel.
Nígbà tí Sanballati ará Horoni àti Tobiah ará a Ammoni tí wọ́n jẹ́ ìjòyè gbọ́ nípa èyí pé, ẹnìkan wá láti mú ìtẹ̀síwájú bá àlàáfíà àwọn ará Israẹli inú bí wọn gidigidi.
11 Astfel, eu am venit la Ierusalim și am stat acolo trei zile.
Mo sì lọ sí Jerusalẹmu, lẹ́yìn ìgbà tí mo dúró níbẹ̀ fún ọjọ́ mẹ́ta.
12 Și m-am sculat noaptea, eu și câțiva bărbați cu mine; nici nu am spus vreunui om ce pusese Dumnezeul meu în inima mea pentru a face la Ierusalim; nici nu era acolo vreun animal cu mine, în afară de animalul pe care călăream.
Mo jáde ní òru pẹ̀lú àwọn ọkùnrin díẹ̀. Èmi kò sì sọ fún ẹnìkankan ohun tí Ọlọ́run mi ti fi sí ọkàn mi láti ṣe fún Jerusalẹmu. Kò sí ẹranko kankan pẹ̀lú mi, bí kò ṣe ọ̀kan ṣoṣo tí mo gùn.
13 Și am ieșit noaptea pe poarta văii, chiar prin fața fântânii dragonului și spre poarta bălegarului și am văzut zidurile Ierusalimului care erau dărâmate și porțile lui mistuite de foc.
Ní òru, mo jáde lọ sí àfonífojì ibodè sí ìhà kànga Jakali àti sí ẹnu ibodè Ààtàn àti ẹnu ibodè rẹ̀ èyí tí ó ti wó odi Jerusalẹmu tí ó lulẹ̀, tí a ti fi iná sun.
14 Atunci am mers la poarta fântânii și la scăldătoarea împăratului; dar nu era loc pentru animalul care era sub mine să treacă.
Nígbà náà ni mo lọ sí ẹnu ibodè orísun àti sí adágún omi ọba, ṣùgbọ́n kò sí ààyè tó fún ẹranko mi láti kọjá;
15 Atunci am urcat eu noaptea pe lângă pârâu și am văzut zidul și m-am dus înapoi și am intrat pe poarta văii și m-am întors.
bẹ́ẹ̀ ni mo gòkè àfonífojì ní òru, mo ń wo odi. Ní ìparí, mo padà sẹ́yìn, mo sì tún wọlé láti ibodè àfonífojì.
16 Și conducătorii nu știau unde mersesem, sau ce făcusem; nici nu spusesem încă aceasta iudeilor, nici preoților, nici nobililor, nici conducătorilor, nici celorlalți care făceau lucrarea.
Àwọn olórí kò mọ ibi tí mo lọ tàbí mọ ohun tí mo ń ṣe, nítorí èmi kò tí ì sọ fún àwọn ará Júù tàbí àwọn àlùfáà tàbí àwọn ọlọ́lá tàbí àwọn ìjòyè tàbí ẹnikẹ́ni mìíràn tí yóò máa ṣe iṣẹ́ náà.
17 Atunci le-am spus: Voi vedeți nenorocirea în care suntem, cum Ierusalimul șade risipit și porțile lui sunt arse cu foc; veniți și să construim zidul Ierusalimului, ca să nu mai fim de ocară.
Nígbà náà ni mo sọ fún wọn pé, “Ṣé ẹ rí wàhálà tí a ni: Jerusalẹmu wà nínú ìparun, ibodè rẹ̀ ni a sì ti fi iná jó. Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a tún odi Jerusalẹmu mọ, àwa kò sì ní jẹ́ ẹni ẹ̀gàn mọ́”.
18 Atunci le-am spus despre mâna Dumnezeului meu care fusese bună peste mine; și de asemenea de cuvintele împăratului pe care mi le spusese. Iar ei au spus: Să ne ridicăm și să construim. Astfel, și-au întărit mâinile pentru această lucrare bună.
Èmi sì tún sọ fún wọn nípa bí ọwọ́ àánú Ọlọ́run mi ṣe wà lára mi àti ohun tí ọba ti sọ fún mi. Wọ́n dáhùn wí pé, “Ẹ jẹ́ kí a bẹ̀rẹ̀ àtúnmọ rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ rere yìí.
19 Dar când Sanbalat horonitul și Tobia, servitorul, amonitul, și Gheșem arabul, au auzit aceasta, au râs de noi în batjocură și ne-au disprețuit și au spus: Ce este acest lucru pe care îl faceți? Vă răzvrătiți împotriva împăratului?
Ṣùgbọ́n nígbà tí Sanballati ará a Horoni, Tobiah ara olóyè Ammoni àti Geṣemu ará a Arabia gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n fi wá ṣe ẹlẹ́yà, wọ́n sì fi wá ṣe ẹ̀sín. Wọ́n béèrè pé, “Kí ni èyí tí ẹ ń ṣe yìí? Ṣé ẹ ń ṣọ̀tẹ̀ sí ọba ni?”
20 Atunci le-am răspuns și le-am zis: Dumnezeul cerului, el ne va face să prosperăm; de aceea noi, servitorii săi, ne vom ridica și vom construi; dar voi nu aveți nici parte, nici drept, nici amintire în Ierusalim.
Mo dá wọn lóhùn, mo wí fún wọn pé, “Ọlọ́run ọ̀run yóò fún wa ní àṣeyọrí. Àwa ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò bẹ̀rẹ̀ láti tún un mọ, ṣùgbọ́n fún un yin, ẹ̀yin kò ní ìpín tàbí ipa tàbí ẹ̀tọ́ ohunkóhun tí ó jẹ mọ́ ìtàn ní Jerusalẹmu.”

< Neemia 2 >