< Ieremia 12 >
1 Drept ești tu, DOAMNE, mă cert cu tine; totuși lasă-mă să vorbesc cu tine despre judecățile tale; Pentru ce prosperă calea celor stricați? Pentru ce sunt fericiți toți cei care se poartă foarte perfid?
Olúwa, olódodo ni ọ́ nígbàkígbà, nígbà tí mo mú ẹjọ́ kan tọ̀ ọ́ wá. Síbẹ̀ èmi yóò bá ọ sọ̀rọ̀ nípa òdodo rẹ. Èéṣe tí ọ̀nà àwọn ènìyàn búburú fi ń ṣe déédé? Èéṣe tí gbogbo àwọn aláìṣòdodo sì ń gbé ní ìrọ̀rùn?
2 Tu i-ai sădit, da, au prins rădăcină: cresc, da, ei aduc rod; tu ești aproape în gura lor și departe de rărunchii lor.
Ó ti gbìn wọ́n, wọ́n sì ti fi egbò múlẹ̀, wọ́n dàgbà wọ́n sì so èso. Gbogbo ìgbà ni ó wà ní ètè wọn, o jìnnà sí ọkàn wọn.
3 Dar tu, DOAMNE, mă cunoști; tu m-ai văzut și mi-ai încercat inima față de tine; trage-i afară ca pe oi pentru măcelărire și pregătește-i pentru ziua măcelului.
Síbẹ̀ o mọ̀ mí ní Olúwa, o ti rí mi o sì ti dán èrò mi nípa rẹ wò. Wọ, wọ́n lọ bí àgùntàn tí a fẹ́ pa. Yà wọ́n sọ́tọ̀ fún ọjọ́ pípa.
4 Cât timp va jeli țara și se vor ofili ierburile de pe fiecare câmp, din cauza stricăciunii celor care locuiesc în ea? Fiarele și păsările sunt mistuite, pentru că ei au spus: El nu va vedea ultimul nostru sfârșit.
Yóò ti pẹ́ tó tí ọ̀gbẹlẹ̀ yóò fi wà, tí gbogbo ewéko igbó sì ń rọ? Nítorí àwọn ènìyàn búburú ni ó ń gbé ibẹ̀. Àwọn ẹranko àti àwọn ẹyẹ ti ṣègbé, pẹ̀lúpẹ̀lú àwọn ènìyàn ń sọ pé, “Kò lè rí ohun tó ṣẹlẹ̀ sí wa.”
5 Dacă ai alergat cu pedeștrii și ei te-au obosit, atunci cum poți tu să te întreci cu caii? Și dacă în țara păcii, în care te încrezi, ei te-au obosit, atunci cum vei face când se umflă Iordanul?
Bí ìwọ bá ń bá ẹlẹ́ṣẹ̀ sáré, tí àárẹ̀ sì mú ọ, báwo ni ìwọ yóò ṣe bá ẹṣin díje? Bí ìwọ bá kọsẹ̀ ní ilẹ̀ àlàáfíà, bí ìwọ bá ní ìgbẹ́kẹ̀lé, kí ni ìwọ ó ṣe nínú ẹkùn odò Jordani?
6 Deoarece chiar frații tăi și casa tatălui tău, chiar ei s-au purtat cu perfidie cu tine; da, au chemat o mulțime după tine; să nu îi crezi când îți vorbesc cuvinte frumoase.
Àwọn arákùnrin rẹ àti àwọn ìdílé ti dà ọ́, kódà wọ́n ti kẹ̀yìn sí ọ, wọ́n ti hó lé ọ lórí. Má ṣe gbà wọ́n gbọ́ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n ń sọ̀rọ̀ rẹ dáradára.
7 Mi-am părăsit casa, mi-am lăsat moștenirea; am dat-o pe preaiubita sufletului meu în mâna dușmanilor ei.
Èmi yóò kọ ilé mi sílẹ̀, èmi yóò fi ìní mi sílẹ̀. Èmi yóò fi ẹni tí mo fẹ́ lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́.
8 Moștenirea mea este pentru mine ca un leu în pădure; strigă împotriva mea: de aceea am urât-o.
Ogún mi ti rí sí mi bí i kìnnìún nínú igbó. Ó ń bú ramúramù mọ́ mi; nítorí náà mo kórìíra rẹ̀.
9 Moștenirea mea este pentru mine ca o pasăre pestriță, păsările de jur împrejur sunt împotriva ei; Veniți, adunați pe toate fiarele câmpului, veniți să mâncați.
Ogún mi kò ha ti rí sí mi bí ẹyẹ kannakánná tí àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ dòyì ka, tí wọ́n sì kọjú ìjà sí i? Ẹ lọ, kí ẹ sì kó gbogbo ẹranko igbó jọ, ẹ mú wọn wá jẹ.
10 Mulți păstori au distrus via mea, au călcat în picioare partea mea, au făcut din partea mea plăcută o pustie părăsită.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ olùṣọ́-àgùntàn ni yóò sì ba ọgbà àjàrà mi jẹ́, tí wọn yóò sì tẹ oko mi mọ́lẹ̀; wọ́n ó sọ oko dídára mi di ibi tí a ń da ìdọ̀tí sí.
11 Ei au pustiit-o, și fiind pustiită, aceasta jelește înaintea mea; toată țara este pustiită, pentru că nimeni nu o pune la inimă.
A ó sọ ọ́ di aṣálẹ̀ ilẹ̀ tí kò wúlò níwájú mi, gbogbo ilẹ̀ ni yóò di ahoro nítorí kò sí ẹnìkankan tí yóò náání.
12 Prădătorii au venit pe toate înălțimile, prin pustie, pentru că sabia DOMNULUI va nimici de la o margine a țării până la cealaltă margine a țării: nicio carne nu va avea pace.
Gbogbo ibi gíga tí ó wà nínú aṣálẹ̀ ni àwọn apanirun ti gorí, nítorí idà Olúwa yóò pa láti ìkangun kìn-ín-ní dé ìkangun èkejì ilẹ̀ náà; kò sí àlàáfíà fún gbogbo alààyè.
13 Ei au semănat grâu dar vor secera spini; s-au supus durerii dar nu le va folosi; și vor fi rușinați de veniturile voastre din cauza mâniei înverșunate a DOMNULUI.
Àlìkámà ni wọn yóò gbìn, ṣùgbọ́n ẹ̀gún ni wọn yóò ká, wọn yóò fi ara wọn ṣe wàhálà, ṣùgbọ́n òfo ni èrè wọn. Kí ojú kí ó tì yín nítorí èrè yín, nítorí ìbínú gbígbóná Olúwa.
14 Astfel spune DOMNUL împotriva tuturor vecinilor mei cei răi, care se ating de moștenirea pe care am dat-o poporului meu Israel să o moștenească: Iată, îi voi smulge din țara lor și voi smulge casa lui Iuda din mijlocul lor.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Ní ti gbogbo àwọn aládùúgbò mi búburú tí wọ́n gbẹ́sẹ̀ lé ogún tí mo fún àwọn ènìyàn Israẹli mi, Èmi yóò fà wọ́n tu kúrò lórí ilẹ̀ wọn, èmi yóò fa ìdílé Juda tu kúrò ní àárín wọn.
15 Și se va întâmpla, după ce îi voi fi smuls că mă voi întoarce și voi avea milă de ei și îi voi aduce înapoi, pe fiecare om la moștenirea lui și pe fiecare om în țara lui.
Ṣùgbọ́n tí mo bá fà wọ́n tu tán, Èmi yóò padà yọ́nú sí wọn. Èmi yóò sì padà fún oníkálùkù ní ogún ìní rẹ̀ pẹ̀lú ilẹ̀ ìní oníkálùkù.
16 Și se va întâmpla, dacă vor învăța cu toată atenția căile poporului meu, ca să jure pe numele meu: DOMNUL trăiește; precum au învățat pe poporul meu să jure pe Baal; atunci vor fi zidiți în mijlocul poporului meu.
Bí wọ́n bá sì kọ ìwà àwọn ènìyàn mi, tí wọ́n sì fi orúkọ mi búra wí pé, ‘Níwọ̀n bí Olúwa ń bẹ láààyè,’ gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti kọ́ àwọn ènìyàn mi láti fi Baali búra, nígbà náà ni a ó gbé wọn ró láàrín àwọn ènìyàn mi.
17 Dar dacă nu vor asculta de mine, voi smulge în întregime și voi nimici acea națiune, spune DOMNUL.
Ṣùgbọ́n bí orílẹ̀-èdè kan kò bá gbọ́, Èmi yóò fà á tu pátápátá, èmi yóò sì pa wọ́n run,” ni Olúwa wí.