< Isaia 48 >

1 Ascultaţi aceasta, casă a lui Iacob, care sunteţi numiţi după numele lui Israel şi aţi ieşit din apele lui Iuda, care juraţi pe numele DOMNULUI şi amintiţi despre Dumnezeul lui Israel, dar nu în adevăr, nici în dreptate.
“Tẹ́tí sí èyí, ìwọ ilé e Jakọbu, ìwọ tí a ń pè pẹ̀lú orúkọ Israẹli tí o sì wá láti ẹ̀ka Juda, ìwọ tí ò ń búra ní orúkọ Olúwa tí o sì ń pe Ọlọ́run Israẹli ṣùgbọ́n kì í ṣe ní òtítọ́ àti òdodo,
2 Fiindcă se numesc pe ei înşişi după cetatea sfântă şi se sprijină pe Dumnezeul lui Israel; DOMNUL oştirilor este numele său.
ìwọ tí ò ń pe ara rẹ ní ọmọ ìlú mímọ́ n nì tí o sì gbẹ́kẹ̀lé Ọlọ́run Israẹli— Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni orúkọ rẹ̀.
3 Am vestit de la început lucrurile din vechime; şi au ieşit din gura mea şi le-am arătat; le-am făcut dintr-odată şi s-au întâmplat.
Èmi sọ àsọtẹ́lẹ̀ àwọn nǹkan ti tẹ́lẹ̀ lọ́jọ́ tó ti pẹ́, ẹnu mi ló ti kéde wọn, mo sì sọ wọ́n di mí mọ̀; lẹ́yìn náà lójijì mo gbé ìgbésẹ̀, wọ́n sì wá sí ìmúṣẹ.
4 Deoarece am ştiut că tu eşti încăpăţânat şi gâtul tău este un tendon de fier şi sprânceana ta de aramă;
Nítorí mo mọ bí ẹ ti jẹ́ olórí kunkun tó; àwọn iṣan ọrùn yín sì jẹ́ irin; bẹ́ẹ̀ ni iwájú yín idẹ ni.
5 Ţi-am vestit de la început; înainte să se fi întâmplat ţi-am arătat, ca nu cumva să spui: Idolul meu le-a făcut şi chipul meu cioplit şi chipul meu turnat le-a poruncit.
Nítorí náà mo ti sọ nǹkan wọ̀nyí fún ọ ní ọjọ́ tí ó ti pẹ́; kí wọn ó tó ṣẹlẹ̀ mo ti kéde wọn fún un yín tó bẹ́ẹ̀ tí ìwọ kò fi lè sọ pé, ‘Àwọn ère mi ló ṣe wọ́n; àwọn ère igi àti òrìṣà irin ló fọwọ́sí i.’
6 Tu ai auzit; priveşte toate acestea; şi refuzaţi să [le] vestiţi? Ţi-am arătat lucruri noi din acest timp, chiar lucruri ascunse şi nu le-ai cunoscut.
Ìwọ ti gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí; wo gbogbo wọn. Ǹjẹ́ o kò nígbà wọ́n bí? “Láti ìsinsin yìí lọ, Èmi yóò máa sọ fún ọ nípa nǹkan tuntun, àwọn nǹkan tí ó fi ara sin tí ìwọ kò mọ̀.
7 Acum sunt create şi nu de la început; chiar înaintea zilei acesteia nu le-ai auzit; ca nu cumva să spui: Iată, le-am ştiut.
A dá wọn ní àkókò yìí kì í ṣe láti ìgbà pípẹ́ ìwọ kò tí ì gbọ́ nípa wọn títí di òní. Nítorí náà, ìwọ kò lè sọ pé, ‘Bẹ́ẹ̀ ni, mo mọ̀ nípa wọn.’
8 Da, nu le-ai auzit; da, nu le-ai cunoscut; da, din acel timp când urechea ta nu a fost deschisă, fiindcă am ştiut că te vei purta foarte perfid şi din pântece ai fost numit un încălcător [de lege].
Ìwọ a ha ti gbọ́ tàbí ó ti yé ọ bí láti ìgbà àtijọ́ etí kò ti di yíyà. Ǹjẹ́ mo mọ̀ bí o ti jẹ́ alárékérekè tó; a ń pè ọ́ ní ọlọ̀tẹ̀ láti ìgbà ìbí rẹ.
9 De dragul numelui meu îmi voi amâna mânia şi pentru lauda mea mă voi abţine pentru tine, ca să nu te stârpesc.
Nítorí orúkọ ara mi, mo dáwọ́ ìbínú mi dúró; nítorí ìyìn ara mi, mo fà á sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ, kí a má ba à ké ọ kúrò.
10 Iată, te-am curăţat, dar nu cu argint; te-am ales în cuptorul de necaz.
Wò ó, èmi ti tún ọ ṣe, bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé kì í ṣe bí i fàdákà; Èmi ti dán ọ wò nínú ìléru ìpọ́njú.
11 De dragul meu, chiar de dragul meu, o voi face, căci cum să fie numele meu murdărit? Şi nu voi da gloria mea altuia.
Nítorí orúkọ mi, nítorí orúkọ mi, mo ṣe èyí. Báwo ni mo ṣe lè jẹ́ kí a ba orúkọ mi jẹ́. Èmi kì yóò fi ògo mi fún ẹlòmíràn.
12 Daţi-mi ascultare, Iacob şi Israel, cei chemaţi ai mei; eu sunt el; eu sunt cel dintâi, şi cel de pe urmă.
“Tẹ́tí sí mi, ìwọ Jakọbu Israẹli ẹni tí mo pè. Èmi ni ẹni náà; Èmi ni ẹni àkọ́kọ́ àti ẹni ìgbẹ̀yìn.
13 Mâna mea de asemenea a întemeiat pământul şi dreapta mea a întins cerurile, când le chem, ele se ridică în picioare împreună.
Ọwọ́ mi pàápàá ni ó fi àwọn ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, àti ọwọ́ ọ̀tún mi ni ó tẹ àwọn ọ̀run; nígbà tí mo pè wọ́n, gbogbo wọn dìde sókè papọ̀.
14 Voi toţi, adunaţi-vă şi ascultaţi; cine dintre ei a vestit aceste lucruri? DOMNUL l-a iubit, el îşi va împlini plăcerea asupra Babilonului şi braţul său va fi asupra caldeenilor.
“Gbogbo yín, ẹ péjọ kí ẹ sì gbọ́. Ta nínú wọn ni ó ti sọ nǹkan wọ̀nyí. Olúwa ti fẹ́ ẹ, yóò sì ṣe ìfẹ́ rẹ̀ ní Babiloni, apá rẹ̀ ni yóò sì wà ní ará àwọn ará Kaldea.
15 Eu, chiar eu, am vorbit; da, l-am chemat, l-am adus şi îşi va face calea prosperă.
Èmi, àní Èmi ló ti sọ̀rọ̀; bẹ́ẹ̀ ni, mo ti pè é. Èmi yóò mú un wá, òun yóò sì ṣe àṣeyọrí nínú ìrìnàjò rẹ̀.
16 Apropiaţi-vă de mine, ascultaţi aceasta; nu am vorbit în taină de la început; de când au fost aceste lucruri, eu sunt acolo; şi acum Domnul DUMNEZEU şi Duhul său m-a trimis.
“Ẹ súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi kí ẹ sì dẹtí sí èyí: “Láti ìgbà ìkéde àkọ́kọ́ èmi kò sọ̀rọ̀ ní ìkọ̀kọ̀; ní àsìkò tí ó sì ṣẹlẹ̀, Èmi wà níbẹ̀.” Àti ní àkókò yìí, Olúwa Olódùmarè ni ó ti rán mi, pẹ̀lú ẹ̀mí rẹ̀.
17 Astfel spune DOMNUL, Răscumpărătorul tău, Cel Sfânt al lui Israel: Eu sunt DOMNUL Dumnezeul tău care te învaţă ce îţi este de folos, care te duce pe calea pe care trebuie să mergi.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí, Olùdáǹdè rẹ, Ẹni Mímọ́ Israẹli: “Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, tí ó kọ́ ọ ní ohun tí ó dára fún ọ, tí ó tọ́ ọ ṣọ́nà tí ó yẹ kí o máa rìn.
18 O de ai fi dat ascultare poruncilor mele! Atunci pacea ta ar fi fost ca un râu şi dreptatea ta ca valurile mării;
Bí ó bá ṣe pé ìwọ bá ti tẹ́tí sílẹ̀ sí àṣẹ mi, àlàáfíà rẹ kì bá ti dàbí ì ti odò, àti òdodo rẹ bí ìgbì Òkun.
19 Sămânţa ta de asemenea ar fi fost ca nisipul şi urmaşii adâncurilor tale ca pietrişul acesteia; numele său nu trebuia nici stârpit, nici nimicit dinaintea mea.
Àwọn ọmọ rẹ ìbá ti dàbí iyanrìn, àwọn ọmọ yín bí i hóró ọkà tí a kò lè kà tán; orúkọ wọn ni a kì yóò ké kúrò tàbí kí a pa wọ́n run níwájú mi.”
20 Ieşiţi din Babilon, fugiţi de caldei, vestiţi cu o voce de cântare, spuneţi aceasta, rostiţi aceasta până la capătul pământului; spuneţi: DOMNUL a răscumpărat pe servitorul său Iacob.
Fi Babeli sílẹ̀, sá fún àwọn ará Babeli, ṣe ìfilọ̀ èyí pẹ̀lú ariwo ayọ̀ kí o sì kéde rẹ̀. Rán an jáde lọ sí òpin ilẹ̀ ayé; wí pé, “Olúwa ti dá ìránṣẹ́ rẹ̀ Jakọbu nídè.”
21 Şi ei nu au însetat când el i-a condus prin pustiuri, a făcut apele să curgă din stâncă pentru ei, a despicat de asemenea stânca şi apele au ţâşnit.
Òrùngbẹ kò gbẹ wọ́n nígbà tí ó kó wọn kọjá nínú aginjù; ó jẹ́ kí omi ó sàn fún wọn láti inú àpáta; ó fọ́ àpáta omi sì tú jáde.
22 Nu este pace pentru cei stricaţi, spune DOMNUL.
“Kò sí àlàáfíà,” ni Olúwa wí, “Fún àwọn ìkà.”

< Isaia 48 >