< 1 Cronici 9 >

1 Astfel tot Israelul a fost numărat după genealogii; și iată, ei au fost scriși în cartea împăraților lui Israel și Iuda, care au fost duși în Babilon pentru fărădelegea lor.
Gbogbo Israẹli ni a kọ lẹ́sẹẹsẹ nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ àwọn baba ńlá nínú ìwé àwọn ọba Israẹli. Àwọn ènìyàn Juda ni a kó ní ìgbèkùn lọ sí Babeli nítorí àìṣòótọ́ wọn.
2 Și primii locuitori care au locuit în stăpânirile lor, în cetățile lor erau: israeliții, preoții, leviții și netinimii.
Nísinsin yìí, àwọn tí ó kọ́kọ́ tún tẹ̀dó lórí ohun ìní wọn ní ìlú wọn ni díẹ̀ nínú àwọn ọmọ Israẹli, àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa.
3 Și în Ierusalim au locuit dintre copiii lui Iuda și dintre copiii lui Beniamin și dintre copiii lui Efraim și Manase;
Àwọn tí ó wá láti Juda láti Benjamini àti láti Efraimu àti Manase tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu jẹ́:
4 Utai, fiul lui Amihud, fiul lui Omri, fiul lui Imri, fiul lui Bani, din copiii lui Farez, fiul lui Iuda.
Uttai ọmọ Ammihudu, ọmọ Omri, ọmọ Imri, ọmọ Bani, ìran ọmọ Peresi ọmọ Juda.
5 Și dintre șiloniți: Asaia, întâiul născut, și fiii lui.
Àti nínú ará Ṣilo: Asaiah àkọ́bí àti àwọn ọmọ rẹ̀.
6 Și dintre fiii lui Zerah: Ieuel și frații lor, șase sute nouăzeci.
Ní ti ará Sera: Jeueli. Àwọn ènìyàn láti Juda sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́wàá.
7 Și dintre fiii lui Beniamin: Salu, fiul lui Meșulam, fiul lui Hodavia, fiul lui Hasenua,
Àti nínú àwọn ọmọ Benjamini ni: Sallu ọmọ Meṣullamu, ọmọ Hodafiah; ọmọ Hasenuah;
8 Și Ibneia, fiul lui Ieroham și Ela, fiul lui Uzi, fiul lui Micri; și Meșulam, fiul lui Șefatia, fiul lui Reuel, fiul lui Ibnia;
Ibinaiah ọmọ Jerohamu; Ela ọmọ Ussi, ọmọ Mikri; àti Meṣullamu ọmọ Ṣefatia; ọmọ Reueli, ọmọ Ibinijah.
9 Și frații lor, conform generațiilor, nouă sute cincizeci și șase. Toți acești bărbați erau mai marii părinților în casa părinților lor.
Àwọn ènìyàn láti Benjamini gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ ọ́ nínú ìran wọn nínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó dín mẹ́rìnlélógójì. Gbogbo àwọn ọkùnrin yí jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé.
10 Și dintre preoți: Iedaeia și Iehoiarib și Iachin,
Ní ti àwọn àlùfáà: Jedaiah; Jehoiaribi; Jakini;
11 Și Azaria, fiul lui Hilchia, fiul lui Meșulam, fiul lui Țadoc, fiul lui Meraiot, fiul lui Ahitub, conducătorul casei lui Dumnezeu;
Asariah ọmọ Hilkiah, ọmọ Meṣullamu, ọmọ Sadoku, ọmọ Meraioti, ọmọ Ahitubu, olórí tí ó ń bojútó ilé Ọlọ́run;
12 Și Adaia, fiul lui Ieroham, fiul lui Pașhur, fiul lui Malchia; și Maesai, fiul lui Adiel, fiul lui Iahzera, fiul lui Meșulam, fiul lui Meșilemit, fiul lui Imer;
Adaiah ọmọ Jerohamu, ọmọ Paṣuri, ọmọ Malkiah; àti Masai ọmọ Adieli, ọmọ Jahisera, ọmọ Meṣullamu ọmọ Meṣilemiti, ọmọ Immeri.
13 Și frații lor, capi ai casei părinților lor, o mie șapte sute șaizeci; bărbați capabili să facă lucrarea serviciului casei lui Dumnezeu.
Àwọn àlùfáà, tí wọ́n jẹ́ àwọn olórí àwọn ìdílé, tí ó jẹ́ ẹgbẹ̀sán ó dín méjì. Wọ́n jẹ́ alágbára ọkùnrin, tí wọ́n lè dúró fún iṣẹ́ ìránṣẹ́ nínú ilé Ọlọ́run.
14 Și dintre leviți: Șemaia, fiul lui Hașub, fiul lui Azricam, fiul lui Hașabia, din fiii lui Merari;
Ní ti àwọn ará Lefi: Ṣemaiah ọmọ Haṣubu, ọmọ Asrikamu, ọmọ Haṣabiah ará Merari;
15 Și Bacbacar, Hereș și Galal și Matania, fiul lui Mica, fiul lui Zicri, fiul lui Asaf;
Bakibakari, Hereṣi, Galali àti Mattaniah, ọmọ Mika, ọmọ Sikri, ọmọ Asafu;
16 Și Obadia, fiul lui Șemaia, fiul lui Galal, fiul lui Iedutun și Berechia, fiul lui Așa, fiul lui Elcana, care au locuit în satele netofatiților.
Obadiah ọmọ Ṣemaiah, ọmọ Galali, ọmọ Jedutuni; àti Berekiah ọmọ Asa, ọmọ Elkana, tí ó ń gbé nínú àwọn ìlú àwọn ará Netofa.
17 Și portarii erau: Șalum și Acub și Talmon și Ahiman și frații lor: Șalum era mai marele,
Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà: Ṣallumu, Akkubu, Talmoni, Ahimani àti arákùnrin wọn, Ṣalumu olóyè wọn,
18 Care până atunci au așteptat în poarta împăratului spre est, ei erau portari în cetele copiilor lui Levi.
ti wà ní ipò ìdúró ní ẹnu-ọ̀nà ọba ní apá ìhà ìlà-oòrùn títí di àkókò yí. Wọ̀nyí ni àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà tí ó jẹ́ ti ìpàgọ́ àwọn ará Lefi.
19 Și Șalum fiul lui Kore, fiul lui Ebiasaf, fiul lui Core și frații săi, din casa tatălui său, coreiții, erau peste munca serviciului, păzitori ai porților tabernacolului; și părinții lor, fiind peste oștirea DOMNULUI, erau păzitori ai intrării.
Ṣallumu ọmọ Kore ọmọ Ebiasafi, ọmọ Kora, àti àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ẹlẹgbẹ́ rẹ̀. Láti ìdílé rẹ̀ (àwọn ará Korati) ni ó dúró fún ṣíṣọ́ ìloro ẹnu-ọ̀nà àgọ́ gẹ́gẹ́ bí baba wọn ti ń dúró fún ṣíṣọ́ àbáwọlé ibùgbé Olúwa.
20 Și Fineas, fiul lui Eleazar, a fost odinioară conducător peste ei și DOMNUL a fost cu el.
Ní ìgbà àkọ́kọ́ Finehasi ọmọ Eleasari jẹ́ olórí fún àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà, Olúwa sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
21 Și Zaharia, fiul lui Meșelemia, era portar al ușii tabernacolului întâlnirii.
Sekariah, ọmọ Meṣelemiah jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àbáwọlé sí àgọ́ ibi ìpàdé.
22 Toți aceștia aleși să fie portari la porți erau două sute doisprezece. Aceștia erau numărați prin genealogiile lor, în satele lor, pe aceștia David și Samuel, văzătorul, i-au rânduit în serviciul lor.
Gbogbo rẹ̀ lápapọ̀, àwọn tí a yàn láti jẹ́ olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ní àwọn ìloro jẹ́ igba ó lé méjìlá. A ka àwọn wọ̀nyí nípa ìdílé ní ìletò wọn. Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà ni a ti yàn sí ipò láti ọ̀dọ̀ Dafidi àti Samuẹli, aríran, nítorí òtítọ́ wọn.
23 Astfel ei și copiii lor au avut supravegherea, prin gărzi, a porților casei DOMNULUI, casa tabernacolului.
Àwọn àti àwọn ọmọ wọn ni ó wà fún ṣíṣọ́ ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa ilé tí a pè ní àgọ́.
24 Portarii erau spre cele patru vânturi: spre est, vest, nord și sud.
Àwọn olùtọ́jú ẹnu-ọ̀nà wà ní igun mẹ́rẹ̀ẹ̀rin: ìlà-oòrùn, ìwọ̀-oòrùn àríwá àti gúúsù.
25 Și frații lor, care erau în satele lor, veneau pentru șapte zile, din când în când, cu ei.
Àwọn arákùnrin wọn ní àwọn ìletò wọn ní láti wá ní àkókò dé àkókò láti pín iṣẹ́ ìsìn wọn fún àkókò ọjọ́ méje.
26 Fiindcă acești leviți, cei patru portari mai mari, erau în serviciul lor rânduit și erau peste cămările și trezoreriile casei lui Dumnezeu.
Ṣùgbọ́n àwọn olórí alábojútó ẹnu-ọ̀nà mẹ́rẹ̀ẹ̀rin tí wọ́n jẹ́ ará Lefi ni a yàn fún àwọn iyàrá àti àwọn àpótí ìṣúra ní ilé Ọlọ́run.
27 Și au locuit de jur împrejurul casei lui Dumnezeu, deoarece sarcina era asupra lor și deschiderea acesteia le aparținea în fiecare dimineață.
Wọ́n á lo gbogbo òru ní dídúró yí ilé Ọlọ́run ká, nítorí wọ́n ní láti ṣọ́ ọ, wọ́n sì ní àṣẹ sí kọ́kọ́rọ́ fún ṣíṣí i ní àràárọ̀.
28 Și unii dintre ei aveau sarcina servirii vaselor, ca să le aducă înăuntru și să le scoată după număr.
Díẹ̀ wà ní ìdí ohun èlò tí à ń lò fún ìsìn ilé Ọlọ́run; wọn a máa kà á nígbà tí wọ́n gbé e wọlé àti nígbà tí a kó wọn jáde.
29 Unii dintre ei de asemenea erau rânduiți să supravegheze vasele și toate uneltele sanctuarului și floarea făinii și vinul și untdelemnul și tămâia și mirodeniile.
Àwọn mìíràn ni a yàn láti bojútó ohun èlò àti gbogbo ohun èlò ilé tí a yà sọ́tọ̀ fún Ọlọ́run, àti ìyẹ̀fun àti ọtí èso àjàrà àti òróró náà, tùràrí àti tùràrí olóòórùn dídùn.
30 Și unii dintre fiii preoților făceau unguent din mirodenii.
Ṣùgbọ́n díẹ̀ nínú àwọn àlùfáà ni ó ń bojútó pípò tùràrí olóòórùn dídùn papọ̀.
31 Și Matitia, unul dintre leviți, care era întâiul născut al lui Șalum coreitul, avea serviciul rânduit peste lucrurile ce erau făcute în tigăi.
Ará Lefi tí a sọ ní Mattitiah àkọ́bí ọmọkùnrin Ṣallumu ará Kora ni a yàn, tí ń ṣe alábojútó ohun tí a dín.
32 Și alții dintre frații lor, dintre fiii chehatiților, erau peste pâinile punerii înainte, să le pregătească în fiecare sabat.
Àti nínú àwọn arákùnrin wọn, nínú àwọn ọmọ Kohati tó ń ṣe ìtọ́jú àkàrà ìfihàn, láti máa pèsè rẹ̀ ní ọjọọjọ́ ìsinmi.
33 Și aceștia sunt cântăreții, mai mari ai părinților leviților, care rămâneau în cămări dar erau liberi, căci erau angajați în acea lucrare zi și noapte.
Àwọn tí wọ́n jẹ́ ọkùnrin, olórí àwọn ìdílé Lefi dúró nínú àgọ́ ilé Olúwa, wọn kò sì ṣe lára iṣẹ́ ìsìn yòókù nítorí wọ́n ń ṣe iṣẹ́ náà lọ́sàn, lóru.
34 Acești mai mari părinți dintre leviți erau mai mari prin toate generațiile lor; aceștia au locuit la Ierusalim.
Gbogbo wọ̀nyí jẹ́ olórí àwọn Lefi, olóyè gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe kọ lẹ́sẹẹsẹ sínú ìtàn ìdílé láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn, wọ́n sì ń gbé ní Jerusalẹmu.
35 Și în Gabaon a locuit tatăl lui Gabaon, Ieiel, numele soției lui era Maaca;
Jeieli baba Gibeoni ń gbé ní Gibeoni. Orúkọ ìyàwó rẹ̀ a máa jẹ́ Maaka,
36 Și întâiul său născut Abdon, apoi Țur și Chiș și Baal și Ner și Nadab,
pẹ̀lú àkọ́bí ọmọkùnrin rẹ̀ jẹ́ Abdoni, tí wọ̀nyí sì ń tẹ̀lé Suri, Kiṣi, Baali, Neri, Nadabu.
37 Și Ghedor și Ahio și Zaharia și Miclot.
Gedori, Ahio, Sekariah àti Mikiloti.
38 Și Miclot a născut pe Șimeam. Și au locuit de asemenea cu frații lor la Ierusalim în fața fraților lor.
Mikiloti jẹ́ baba Ṣimeamu, àwọn náà ń gbé ní ẹ̀bá ìbátan wọn ní Jerusalẹmu.
39 Și Ner a născut pe Chiș; și Chiș a născut pe Saul; și Saul a născut pe Ionatan și pe Malchi-Șua și pe Abinadab și pe Eșbaal.
Neri jẹ́ baba Kiṣi, Kiṣi baba a Saulu, àti Saulu baba a Jonatani, àti Malikiṣua, Abinadabu àti Eṣi-Baali.
40 Și fiul lui Ionatan era Merib-Baal; și Merib-Baal a născut pe Mica.
Ọmọ Jonatani: Meribu-Baali, tí ó jẹ́ baba Mika.
41 Și fiii lui Mica erau: Piton și Melec și Tahrea și Ahaz.
Àwọn ọmọ Mika: Pitoni. Meleki, Tarea àti Ahasi.
42 Și Ahaz a născut pe Iaera; și Iaera a născut pe Alemet și pe Azmavet și pe Zimri; și Zimri a născut pe Moța;
Ahasi jẹ́ baba Jada, Jada jẹ́ baba Alemeti, Asmafeti, Simri, sì Simri jẹ́ baba Mosa.
43 Și Moța a născut pe Binea; și Refaia, fiul său; Eleasa, fiul său; Ațel, fiul său.
Mosa jẹ́ baba Binea; Refaiah jẹ́ ọmọ rẹ̀, Eleasa ọmọ rẹ̀ àti Aseli ọmọ rẹ̀.
44 Și Ațel a avut șase fii, a căror nume sunt acestea: Azricam, Bocru și Ismael și Șearia și Obadia și Hanan; aceștia erau fiii lui Ațel.
Aseli ní ọmọ mẹ́fà, pẹ̀lú wọ̀nyí ni orúkọ wọn: Asrikamu, Bokeru, Iṣmaeli Ṣeariah, Obadiah àti Hanani, gbogbo wọ̀nyí ni ọmọ Aseli.

< 1 Cronici 9 >