< Psalmów 82 >

1 Psalm Asafa. Bóg stoi w zgromadzeniu Bożym, pośród bogów sprawuje sąd:
Saamu ti Asafu. Ọlọ́run ń ṣàkóso nínú ìpéjọpọ̀ ńlá, ó ṣe ìdájọ́ láàrín àwọn “ọlọ́run òrìṣà”.
2 Jak długo będziecie sądzić niesprawiedliwie i trzymać stronę niegodziwych? (Sela)
“Yóò ti pẹ́ tó tí ìwọ yóò máa gbèjà àwọn aláìṣòdodo kí ó sì ṣe ojú ìṣáájú sí àwọn ènìyàn búburú?
3 Bierzcie w obronę ubogiego i sierotę, oddajcie sprawiedliwość strapionemu i potrzebującemu.
Gbèjà àwọn aláìlágbára àti aláìní baba; ṣe ìtọ́jú ẹ̀tọ́ àwọn aláìní àti ẹni ìnilára.
4 Wyzwólcie biedaka i nędzarza, ocalcie go z ręki niegodziwych.
Gba àwọn aláìlágbára àti aláìní; gbà wọ́n kúrò lọ́wọ́ àwọn ènìyàn búburú.
5 [Lecz oni] nic nie wiedzą i nie rozumieją, ciągle chodzą w ciemności; zachwiały się wszystkie fundamenty ziemi.
“Wọn kò mọ̀ ohun kankan, wọn kò lóye ohun kankan. Wọn ń rìn kiri nínú òkùnkùn; à si mí gbogbo ìpìlẹ̀ ayé.
6 Powiedziałem: Jesteście bogami i wszyscy wy jesteście synami Najwyższego.
“Mo wí pé, ‘Ẹyin ní “Ọlọ́run òrìṣà”; ẹ̀yin ní gbogbo ọmọ Ọ̀gá-ògo jùlọ.’
7 Lecz pomrzecie jak [inni] ludzie i upadniecie jak jeden z książąt.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ó kú bí ènìyàn lásán; ẹ̀yin ó ṣubú bí ọ̀kan nínú ọmọ-aládé.”
8 Powstań, Boże, osądź ziemię, bo ty otrzymasz w dziedzictwo wszystkie narody.
Dìde, Ọlọ́run, ṣe ìdájọ́ ayé, nítorí gbogbo orílẹ̀-èdè ni ìní rẹ.

< Psalmów 82 >