< Księga Sędziów 15 >

1 I stało się po kilku dni, pod czas żniwo pszenicznego, że nawiedził Samson żonę swoję, wziąwszy koźlę z stada, i mówił: Wnijdę do żony mojej do komory; ale mu nie dopuścił ojciec jej wnijść.
Lẹ́yìn ìgbà díẹ̀, ní àkókò ìkórè alikama, Samsoni mú ọ̀dọ́ ewúrẹ́ kan láti bẹ ìyàwó rẹ̀ wò. Ó ní, “Èmi yóò wọ yàrá ìyàwó mi lọ.” Ṣùgbọ́n baba rẹ̀ kò gbà á láààyè láti wọlé.
2 Bo rzekł ojciec jej, mówiąc: Mniemałem, żeś ją miał w nienawiści; przetoż dałem ją towarzyszowi twemu; azaż siostra jej młodsza nie jest cudniejsza nad nię? weźmijże ją sobie miasto niej.
Baba ìyàwó dá a lóhùn pé, “Ó dá mi lójú pé o kórìíra rẹ̀, torí náà mo ti fi fún ọ̀rẹ́ rẹ, ṣe bí àbúrò rẹ̀ obìnrin kò ha lẹ́wà jùlọ? Fẹ́ ẹ dípò rẹ̀.”
3 I odpowiedział im Samson: Już teraz nie będę winien napotem Filistynom, choć im uczynię co złego.
Samsoni dáhùn pé, “Ní àkókò yìí tí mo bá ṣe àwọn Filistini ní ibi èmi yóò jẹ́ aláìjẹ̀bi.”
4 Odszedłszy tedy Samson ułapał trzy sta liszek, a nabrawszy pochodni, przywiązał ogon do ogona, i uwiązał pochodnią jednę między dwoma ogonami w pośrodku.
Samsoni sì jáde lọ, ó mú ọ̀ọ́dúnrún kọ̀lọ̀kọ̀lọ̀ ó so ìrù wọn mọ́ ara wọn ní méjì méjì. Ó mú ètùfù iná, ó so ó mọ́ àwọn ìrù tí ó so pọ̀.
5 Potem zapaliwszy ogniem pochodnie, rozpuścił je między zboża Filistyńskie, i popalił tak stogi jako zboża stojące, i winnice z oliwnicami.
Ó fi iná ran àwọn ètùfù tí ó so náà, ó sì jọ̀wọ́ wọn lọ́wọ́ lọ sínú àwọn oko ọkà àwọn Filistini. Ó jó àwọn pòpóòrò ọkà tí ó dúró àti àwọn tí a dì ní ìtí, ìtí, pẹ̀lú àwọn ọgbà àjàrà àti olifi.
6 Tedy rzekli Filistynowie: Któż to uczynił? I odpowiedziano: Samson, zięć Tamnatczyków, przeto że mu wziął żonę jego, a dał ją towarzyszowi jego. Poszli tedy Filistynowie, i spalili ją i ojca jej ogniem.
Nígbà tí àwọn Filistini béèrè pé, “Ta ni ó ṣe èyí?” Wọ́n dá wọn lóhùn pé, “Samsoni ará Timna ni, nítorí a gba ìyàwó rẹ̀ fún ọ̀rẹ́ rẹ̀.” Nítorí náà àwọn Filistini lọ wọ́n sì sun obìnrin náà àti baba rẹ̀.
7 Którym rzekł Samson: Chociaście to uczynili, przecięć się ja pomszczę nad wami, a potem przestanę.
Samsoni sọ fún un pé, “Nítorí pé ẹ̀yin ṣe èyí, èmi ó gbẹ̀san lára yín, lẹ́yìn náà èmi yóò sì dẹ́kun.”
8 A tak potłukł je okrutnie od biódr aż do goleni, a odszedłszy mieszkał na wierzchu opoki Etam.
Ó kọlù wọ́n pẹ̀lú ìbínú àti agbára ńlá, ó sì pa ọ̀pọ̀lọpọ̀ nínú wọn. Lẹ́yìn náà ni ó lọ, ó sì dúró nínú ihò àpáta kan nínú àpáta Etamu.
9 Przyciągnęli tedy Filistynowie, a położywszy się obozem w Juda, rozciągnęli się aż do Lechy.
Àwọn ará Filistini sì dìde ogun sí Juda, wọ́n ti tan ara wọn ká sí agbègbè Lehi.
10 Tedy rzekli mężowie Juda: Przeczżeście wyciągnęli przeciwko nam? I odpowiedzieli: Przyszliśmy, abyśmy związali Samsona, i uczynili mu, jako on nam uczynił.
Àwọn ọkùnrin Juda sì béèrè pé, “Èéṣe tí ẹ fi wá gbóguntì wá?” Ìdáhùn wọn ni pé, “A wá láti mú Samsoni ní ìgbèkùn, kí a ṣe sí i bí òun ti ṣe sí wa.”
11 A tak wyszło trzy tysiące mężów z Juda na wierzch opoki Etam, i mówili do Samsona: Azaż nie wiesz, że panują nad nami Filistynowie? I cóżeś nam to uczynił? I odpowiedział im: Jako mi uczynili, i takiem im uczynił.
Nígbà náà ni ẹgbẹ̀rún mẹ́ta ọkùnrin láti Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí ihò àpáta nínú àpáta Etamu, wọ́n sì sọ fún Samsoni pé, “Kò ti yé ọ pé àwọn Filistini ní ń ṣe alákòóso lórí wa? Kí ni o ṣe sí wa?” Òun sì dáhùn pé, “Ohun tí wọ́n ṣe sí mi ni èmi náà ṣe sí wọn.”
12 I rzekli mu: Przyszliśmy, abyśmy cię związali, i wydali w ręce Filistynów; którym odpowiedział Samson: Przysiężcie mi, że się na mię sami nie targniecie.
Wọ́n wí pé, “Àwa wá láti dè ọ́, kí a sì fi ọ́ lé àwọn Filistini lọ́wọ́.” Samsoni wí pé, “Ẹ búra fún mi pé, ẹ̀yin kì yóò fúnra yín pa mí.”
13 A oni mu rzekli, mówiąc: Nie, tylko związawszy cię, wydamy cię w ręce ich; ale cię nie zabijemy. A tak związali go dwoma powrozami nowemi, i sprowadzili go z opoki.
“Àwa gbà,” ni ìdáhùn wọn. “Àwa yóò kàn dè ọ́, àwa yóò sì fi ọ́ lé wọn lọ́wọ́, àwa kì yóò pa ọ́.” Wọ́n sì dé pẹ̀lú okùn tuntun méjì, wọ́n sì mú u jáde wá láti ihò àpáta náà.
14 Który gdy przyszedł aż do Lechy, tedy Filistynowie krzycząc bieżeli przeciw niemu; ale Duch Pański przypadł nań, i stały się powrozy, które były na ramionach jego, jako nici lniane ogniem spalone, i rozerwały się związki z rąk jego.
Bí ó ti súnmọ́ Lehi, àwọn Filistini ń pariwo bí wọ́n ṣe ń tò bọ̀. Ẹ̀mí Olúwa bà lé e pẹ̀lú agbára. Àwọn okùn ọwọ́ rẹ̀ dàbí òwú tí ó jóná, ìdè ọwọ́ rẹ̀ já kúrò ní ọwọ́ rẹ̀.
15 Tedy znalazłszy czeluść oślą świeżą, a wyciągnąwszy po nię rękę swoję, wziął ją, i zabił nią tysiąc mężów.
Nígbà tí ó rí egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tuntun kan, ó mú un, ó sì fi pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.
16 Zatem rzekł Samson: Czeluścią oślą kupę jednę albo dwie kupy, a czeluścią oślą zabiłem tysiąc mężów.
Samsoni sì wí pé, “Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo sọ wọ́n di òkìtì kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́. Pẹ̀lú egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ kan, mo ti pa ẹgbẹ̀rún ọkùnrin.”
17 A gdy przestał mówić, porzucił czeluść z ręki swej, i nazwał miejsce ono Ramat Lechy.
Nígbà tí ó dákẹ́ ọ̀rọ̀ í sọ, ó ju egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ náà nù, wọ́n sì pe ibẹ̀ ní Ramati-Lehi (ìtumọ̀ rẹ̀ jẹ́ egungun àgbọ̀n ìsàlẹ̀ pa).
18 Zatem upragnął bardzo, i zawołał do Pana mówiąc: Tyś dał przez rękę sługi twego to wybawienie wielkie, a teraz umrę od pragnienia, albo wpadnę w ręce nieobrzezańców.
Nítorí tí òǹgbẹ gbẹ ẹ́ gidigidi, ó ké pe Olúwa, wí pé, “Ìwọ ti fún ìránṣẹ́ ní ìṣẹ́gun tí ó tóbi yìí. Ṣé èmi yóò ha kú pẹ̀lú òǹgbẹ, kí èmi sì ṣubú sí ọwọ́ àwọn aláìkọlà ènìyàn?”
19 A tak rozszczepił Bóg skałę w Lechy, i wyszły z niej wody, i napił się, i wrócił się duch jego a ożył; przetoż nazwał imię onego źródła: źródło wzywającego, które jest w Lechy aż do dnia dzisiejszego.
Nígbà náà ni Ọlọ́run la kòtò ìsun omi tí ó wà ní Lehi, omi sì tú jáde láti inú rẹ̀. Nígbà tí Samsoni mú mi tan, agbára rẹ̀ sì padà, ọkàn sì sọjí, fún ìdí èyí wọ́n pe ìsun omi náà ni. Ẹni Hakkore (orísun ẹni tí ó pe Ọlọ́run) èyí tí ó sì wà ní Lehi di òní.
20 I sądził lud Izraelski za dni Filistynów przez dwadzieścia lat.
Samsoni ṣe ìdájọ́ Israẹli fún ogún ọdún ní àkókò àwọn ará Filistini.

< Księga Sędziów 15 >