< Jozuego 19 >
1 Potem padł los wtóry Symeonowi, pokoleniu synów Symeonowych według domów ich, a było dziedzictwo ich w pośród dziedzictwa synów Judowych.
Kèké kejì jáde fún ẹ̀yà Simeoni, ní agbo ilé, ní agbo ilé. Ìní wọn sì wà ní àárín ilẹ̀ Juda.
2 A dostało się im w dziedzictwo ich Beerseba, i Seba, i Molada;
Lára ìpín wọn ní: Beerṣeba (tàbí Ṣeba), Molada,
3 I Hasersual, i Bala, i Asem;
Hasari-Ṣuali, Bala, Esemu,
4 I Etolat, i Betul, i Horma;
Eltoladi, Betuli, Horma,
5 I Syceleg, i Bet Marchabot, i Hasersusa,
Siklagi, Beti-Markaboti, Hasari Susa,
6 I Betlebaot, i Serohem, i trzynaście miast, i wsi ich;
Beti-Lebaoti àti Ṣarueli, ìlú wọn jẹ́ mẹ́tàlá àti ìletò wọn.
7 Ain, Remmon, i Atar, i Asan, miasta cztery, i wsi ich;
Aini, Rimoni, Eteri àti Aṣani, ìlú wọn jẹ́ mẹ́rin àti ìletò wọn,
8 I wszystkie wsi, które były około tych miast, aż do Baalatbeer, i Ramat ku stronie południowej. Toć jest dziedzictwo pokolenia synów Symeonowych według domów ich.
àti gbogbo àwọn agbègbè ìlú wọ̀nyí títí dé Baalati-Beeri (Rama ní gúúsù). Èyí ni ilẹ̀ ìní ẹ̀yà àwọn ọmọ Simeoni, agbo ilé, ní agbo ilé.
9 Z działu synów Judowych dostało się dziedzictwo synom Symeonowym, bo dział synów Judowych był wielki dla nich; przetoż wzięli dziedzictwo synowie Symeonowi pośród dziedzictwa ich.
A mú ogún ìní àwọn ọmọ Simeoni láti ìpín Juda, nítorí ìpín Juda pọ̀ ju èyí tí wọ́n nílò lọ. Báyìí ni àwọn ọmọ Simeoni gba ìní wọn ní àárín ilẹ̀ Juda.
10 Potem padł los trzeci synom Zabulonowym według domów ich, a jest granica dziedzictwa ich.
Kèké kẹta jáde fún Sebuluni, ní agbo ilé ní agbo ilé ààlà ìní wọn sì lọ títí dé Saridi.
11 A idzie granica ich morza Marala, i przychodzi do Debbaset, ciągnąc się aż do potoku, który jest przeciw Jeknoam.
Ó sì lọ sí ìwọ̀-oòrùn ní Marala, ó sì dé Dabbeṣeti, ó sì lọ títí dé odo ní ẹ̀bá Jokneamu.
12 I wraca się od Saryd na wschód słońca ku granicy Chasalek Tabor, a stamtąd bieży do Daberet, i ciągnie się do Jafije;
Ó sì yípadà sí ìlà-oòrùn láti Saridi sí ìhà ìlà-oòrùn dé ilẹ̀ Kisiloti-Tabori, ó sì lọ sí Daberati, ó sì gòkè lọ sí Jafia.
13 Potem stamtąd bieży na wschód słońca do Gethefer i do Itakasyn, a wychodzi w Rymmon, i kołem idzie do Nehy.
Nígbà náà ní o lọ sí ìhà ìlà-oòrùn lọ sí Gati-Heferi àti Eti-Kaṣini, ó sì jáde ní Rimoni, ó sì yí sí ìhà Nea.
14 Idzie także kołem taż granica od północy ku Hannaton, a kończy się u doliny Jeftael.
Ní ibẹ̀, ààlà sì yíká ní ìhà àríwá lọ sí Hnatoni ó sì pín ní àfonífojì Ifita-Eli.
15 I Katet, i Nahalal, i Symeron, i Jedala, i Betlehem, miast dwanaście, i wsi ich.
Lára wọn ni Katati, Nahalali, Ṣimroni, Idala àti Bẹtilẹhẹmu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlá àti ìletò wọn.
16 Toć jest dziedzictwo synów Zabulonowych według domów ich, te miasta i wsi ich.
Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní Sebuluni, ní agbo ilé agbo ilé.
17 Isascharowi też padł los czwarty, to jest, synom Isascharowym według domów ich.
Kèké kẹrin jáde fún Isakari, agbo ilé ní agbo ilé.
18 A była granica ich Jezreel, i Chasalot, i Sunem.
Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Jesreeli, Kesuloti, Ṣunemu,
19 I Hafaraim, i Seon, i Anaharat;
Hafraimu, Ṣihoni, Anaharati,
20 I Rabbot, i Cesyjom, i Abes;
Rabiti, Kiṣioni, Ebesi,
21 I Ramet, i Engannim, i Enhadda, i Betfeses.
Remeti, Eni-Gannimu, Eni-Hada àti Beti-Pasesi.
22 A przychodzi granica ich do Taboru, i do Sehesyma, i do Betsemes, a kończą się granice ich u Jordanu, miast szesnaście, i wsi ich.
Ààlà náà sì dé Tabori, Ṣahasuma, àti Beti-Ṣemeṣi, ó sì pin ní Jordani. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mẹ́rìndínlógún àti ìletò wọn.
23 Toć jest dziedzictwo pokolenia synów Isascharowych według domów ich, te miasta i wsi ich.
Ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn jẹ́ ìní ẹ̀yà Isakari, ní agbo ilé agbo ilé.
24 Potem padł los piąty pokoleniu synów Asur według domów ich.
Kèké karùn-ún jáde fún ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
25 I była granica ich: Helkat, i Chali, i Beten, i Achsaf;
Lára ilẹ̀ wọn ni èyí: Helikati, Hali, Beteni, Akṣafu,
26 I Elmelech, i Amaad, i Aessal, a idzie na Karmel do morza, i do Sychor, i Lobanat.
Allameleki, Amadi, àti Miṣali. Ní ìhà ìwọ̀-oòrùn ààlà náà dé Karmeli àti Ṣihori-Libinati.
27 Stamtąd się obraca na wschód słońca ku Betdagon, i bieży aż do Zabulon, i do doliny Jeftach El na północy, Betemek i do Nehyjel, wychodząc do Kabul ku lewej stronie;
Nígbà náà ni o yí sí ìhà ìlà-oòrùn Beti-Dagoni, dé Sebuluni àti àfonífojì Ifita-Eli, ó sì lọ sí àríwá sí Beti-Emeki àti Neieli, ó sì kọjá lọ sí Kabulu ní apá òsì.
28 I do Hebronu, i Rohob, i Hamon, i Kana, aż do Sydonu wielkiego.
Ó sì lọ sí Abdoni, Rehobu, Hammoni àti Kana títí dé Sidoni ńlá.
29 A wraca się ta granica od Rama aż do miasta Zor obronnego; stamtąd się obraca ta granica aż do Hosa, a kończy się u morza podle działu Achsyba.
Ààlà náà sì tẹ̀ sí ìhà Rama, ó sì lọ sí ìlú olódi Tire, ó sì yà sí Hosa, ó sì jáde ní Òkun Ńlá ní ilẹ̀ Aksibu,
30 I Amma, i Afek, i Rohob, miast dwadzieścia i dwa, i wsi ich.
Uma, Afeki àti Rehobu. Wọ́n sì jẹ́ ìlú méjìlélógún àti ìletò wọn.
31 Toć jest dziedzictwo pokolenia synów Aser według domów ich; te miasta i wsi ich.
Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Aṣeri, ní agbo ilé agbo ilé.
32 Potem synom Neftalimowym padł los szósty, synom Neftalimowym według domów ich.
Ìpín kẹfà jáde fún Naftali, agbo ilé ní agbo ilé,
33 I była granica ich od Helef, i od Helon, do Saannanim, i Adami, które jest Necheb, i Jebnael, aż ku Lekum, i kończy się u Jordanu.
ààlà wọn lọ láti Helefi àti igi ńlá ní Saananimu nímù; kọjá lọ sí Adami Nekebu àti Jabneeli dé Lakkumu, ó sì pín ní Jordani.
34 Potem się obraca ta granica ku morzu do Asanot Tabor; a stamtąd bieży ku Hukoka, i idzie do Zabulonu na południe, a do Asar przychodzi ku zachodu, a do Juda ku Jordanowi na wschód słońca.
Ààlà náà gba ìhà ìwọ̀-oòrùn lọ sí Asnoti-Tabori ó sì jáde ní Hukoki. Ó sì dé Sebuluni, ní ìhà gúúsù Aṣeri ní ìhà ìwọ̀-oòrùn àti Juda ní Jordani ní ìhà ìlà-oòrùn.
35 A miasta obronne są: Assedym Ser, i Emat, Rekat, i Cyneret;
Àwọn ìlú olódi sì Siddimu, Seri, Hamati, Rakàti, Kinnereti,
36 I Edama, i Arama, i Asor,
Adama, Rama Hasori,
37 I Kiedes, i Edrej, i Enhasor;
Kedeṣi, Edrei, Eni-Aṣọri,
38 I Jeron, i Magdalel, Horem, i Betanat, i Betsemes, miast dziewiętnaście, i wsi ich.
Ironi, Migdali-Eli, Horemu, Beti-Anati àti Beti-Ṣemeṣi. Wọ́n sì jẹ́ ìlú mọ́kàndínlógún àti ìletò wọn.
39 Toć jest dziedzictwo pokolenia synów Neftalimowych według domów ich; te miasta i wsi ich.
Àwọn ìlú wọ̀nyí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Naftali, ní agbo ilé sí agbo ilé.
40 Potem pokoleń synów Dan według domów ich, padł los siódmy.
Ìbò kéje jáde fún ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé ní agbo ilé.
41 A była granica dziedzictwa ich: Saraa, i Estaol, i Isremes;
Ilẹ̀ ìní wọn nìwọ̀nyí: Sora, Eṣtaoli, Iri-Ṣemesi,
42 I Selebim, i Ajalon, i Jetela;
Ṣaalabini, Aijaloni, Itila,
43 I Elon, i Temnata, i Ekron;
Eloni, Timna, Ekroni,
44 I Eltekie, i Gebbeton i Baalat;
Elteke, Gibetoni, Baalati,
45 I Jehut, i Bane Barak, i Getremmon;
Jehudu, Bene-Beraki, Gati-Rimoni,
46 I Mehajarkon, i Rakon z granicą przeciwko Joppie.
Me Jakoni àti Rakkoni, pẹ̀lú ilẹ̀ tí ó kọjú sí Joppa.
47 Ale granica synów Danowych była bardzo mała; przetoż wyszedłszy synowie Dan dobywali Lesem, i wzięli je, i wysiekli je ostrzem miecza, i wziąwszy je w dziedzictwo mieszkali w niem; i przezwali Lesem Dan według imienia Dana, ojca swego.
(Ṣùgbọ́n àwọn ará Dani ní ìṣòro láti gba ilẹ̀ ìní wọn, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n gòkè lọ, wọ́n sì kọlu Leṣemu, wọ́n sì gbà á, wọ́n sì fi idà kọlù ú, wọ́n sì ń gbé ibẹ̀. Wọ́n sì ń gbé ní Leṣemu, wọ́n sì pe orúkọ rẹ̀ ní Dani orúkọ baba ńlá wọn).
48 Toć jest dziedzictwo pokolenia synów Danowych według domów ich; te miasta, i wsi ich.
Àwọn ìlú wọ́n yí àti ìletò wọn ní ìní ẹ̀yà Dani, ní agbo ilé agbo ilé.
49 A gdy przestali dzielić ziemię według granic jej, tedy dali synowie Izraelscy dziedzictwo Jozuemu, synowi Nunowemu, w pośród siebie.
Nígbà tí wọ́n ti parí pínpín ilẹ̀ náà ní ìpín ti olúkúlùkù, àwọn ará Israẹli fún Joṣua ọmọ Nuni ní ìní ní àárín wọn,
50 Według rozkazania Pańskiego dali mu miasto, którego żądał, Tamnat Saraa na górze Efraim, gdzie zbudował miasto, i mieszkał w niem.
bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n fún un ni ìlú tí ó béèrè fún, Timnati Serah ní ìlú òkè Efraimu. Ó sì kọ́ ìlú náà, ó sì ń gbé ibẹ̀.
51 Teć są dziedzictwa, które losem podzielili w osiadłość Eleazar kapłan, i Jozue, syn Nunów, i przedniejsi z ojców pokolenia synów Izraelskich w Sylo przed Panem, u drzwi namiotu zgromadzenia, i dokończyli podziału ziemi.
Wọ̀nyí ni àwọn ilẹ̀ tí Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni àti àwọn olórí ẹ̀yà agbo ilé Israẹli fi ìbò pín ní Ṣilo ní iwájú Olúwa ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Báyìí ni wọ́n parí pínpín ilẹ̀ náà.