< I Kronik 28 >
1 Tedy zgromadził Dawid wszystkich książęt Izraelskich, i przedniejszych z każdego pokolenia, i przełożonych nad hyfcami, którzy służyli królowi, i półkowników, i rotmistrzów, i przełożonych nad wszystką majętnością i osiadłością królewską; synów też swoich z komornikami, i z innymi możnymi, i ze wszystkim ludem rycerskim do Jeruzalemu.
Dafidi pe gbogbo àwọn oníṣẹ́ ti Israẹli láti péjọ ní Jerusalẹmu. Àwọn ìjòyè lórí àwọn ẹ̀yà, àwọn alákòóso ìpín nínú iṣẹ́ bí ọba, àwọn alákòóso ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn alákòóso ọ̀rọ̀ọ̀rún àti àwọn oníṣẹ́ tí ó wà ní ìdí bíbojútó gbogbo àwọn ẹrù àti ohun ọ̀sìn tí ó jẹ́ ti ọba àti àwọn ọmọ rẹ̀ pẹ̀lú ààfin àwọn oníṣẹ́ ààfin, àwọn ọkùnrin alágbára àti gbogbo àwọn ògbójú jagunjagun lápapọ̀.
2 A powstawszy król Dawid na nogi swoje, rzekł: Słuchajcie mię, bracia moi, i ludu mój! Jam był umyślił w sercu swem, budować dom, gdzieby odpoczywała skrzynia przymierza Paćskiego, i na podnóżek nóg Boga naszego, i zgotowałem był potrzeby ku budowaniu;
Ọba Dafidi dìde dúró ní ẹsẹ̀ rẹ̀, o sì wí pé, “Fetísílẹ̀ sí mi, ẹ̀yin ará mi àti ẹ̀yin ènìyàn mi. Èmi ní o ni lọ́kàn mi láti kọ́ ilé gẹ́gẹ́ bí ibi ìsinmi fún àpótí ẹ̀rí tí Olúwa fún àpótí ìtìsẹ̀ Ọlọ́run wa, èmi sì gbèrò láti kọ́ ọ.
3 Ale Bóg rzekł do mnie: Nie będziesz budował domu imieniowi memu, przeto żeś mąż waleczny, i rozlewałeś krew.
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún mi pé, ‘Ìwọ kò gbọdọ̀ kọ́ ilé fún orúkọ mi, nítorí ìwọ jẹ́ jagunjagun, ìwọ sì ti tàjẹ̀ sílẹ̀.’
4 Ale obrał mię Pan, Bóg Izraelski, ze wszystkiego domu ojca mego, abym był królem nad Izraelem na wieki; bo z Judy obrał księcia, a z narodu Judzkiego dom ojca mego; i z synów ojca mego upodobał mię sobie za króla nad wszystkim Izraelem.
“Síbẹ̀ Olúwa, Ọlọ́run Israẹli yàn mí láti gbogbo ìdílé láti jẹ́ ọba lórí Israẹli, títí láé. Ó yan Juda gẹ́gẹ́ bí olórí, àti láti ilé Juda, ó yan ìdílé mi, àti láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ baba à mí, ó tẹ́ Ẹ lọ́rùn láti fi mí ṣe ọba lórí gbogbo Israẹli.
5 A ze wszystkich synów moich (bo mi wiele synów Pan dał) obrał Salomona, syna mego, aby siedział na stolicy królestwa Pańskiego nad Izraelem.
Nínú gbogbo àwọn ọmọ mi pẹ̀lú Olúwa ti fún mi ní púpọ̀, ó ti yan ọmọ mi Solomoni láti jókòó lórí ìtẹ́ ìjọba ti Olúwa lórí Israẹli.
6 I mówił do mnie: Salomon, syn twój, ten zbydyje dom mój, i przysionki moje; albowiemem go sobie obrał za syna, a Ja mu będę za ojca.
Ó wí fún mi pé, Solomoni ọmọ rẹ ni ẹni tí yóò kọ́ ilé mi àti àwọn ààfin mi, nítorí tí èmi ti yàn án láti ṣe ọmọ mi èmi yóò sì jẹ́ baba a rẹ̀.
7 I umocnię królestwo jego aż na wieki, będzieli statecznym w pełnieniu przykazań moich i sądów moich, jako i dziś.
Èmi yóò fi ìdí ìjọba rẹ̀ kalẹ̀ títí láé tí kò bá kọ̀ láti gbé àṣẹ àti òfin mi jáde, gẹ́gẹ́ bí a ti ṣe é ní àsìkò yìí.
8 Teraz tedy mówię wam pezed obliczem wszystkiego Izraela, zgromadzenia tego Pańskiego, gdzie słyszy Bóg nasz: Strzeżcie a szukajcie wszystkich rozkazań Pana, Boga waszego, abyście osiedli ziemię dobrą, i zostawili ją w dziedzictwo synom swoim po so bie aż na wieki.
“Bẹ́ẹ̀ ni, nísinsin yìí, èmi pàṣẹ fún ọ ní ojú gbogbo Israẹli àti ní ti ìpéjọpọ̀ tí Olúwa, àti ní etí ìgbọ́ Ọlọ́run wa. Ṣọ́ra kó o sì tẹ̀lé gbogbo òfin Olúwa Ọlọ́run rẹ kí ìwọ kí ó le jogún ilẹ̀ dáradára yìí, kí o sì mú un lọ síwájú gẹ́gẹ́ bí ogún rẹ fún àwọn ìran ọmọ rẹ títí láé.
9 A ty Salomonie, synu mój! znaj Boga, ojca twojego, i służ mu sercem doskonałem, i umysłem dobrowolnym; bo wszystkie serca przegląda Pan, i wszystkie zamusły myśli zna. Jeźli go szukać bądziesz, znajdziesz go, a jeźli go opuścisz, odrzuci cię na wieki.
“Àti ìwọ, ọmọ mi Solomoni, rántí Ọlọ́run baba à rẹ, kí o sì sìn ín pẹ̀lú tọkàntọkàn pẹ̀lú ìfọkànsí pẹ̀lú ọkàn tí ó pé, nítorí Olúwa ṣàwárí gbogbo ọkàn ó sì mọ gbogbo èrò. Tí ìwọ bá wá a, ìwọ yóò rí i; ṣùgbọ́n tí ìwọ bá kọ̀ ọ́ sílẹ̀, òun yóò kọ̀ ọ́ títí láé.
10 Obaczże teraz, iż cię Pan obrał, abyś zbudował dom świątnicy; zmacniajże się a wykonaj to.
Gbèrò báyìí nítorí tí Olúwa ti yàn ọ́ láti kọ́ ilé Olúwa gẹ́gẹ́ bí ilé tí a yà sí mímọ́ fún Olúwa. Jẹ́ alágbára kí ó sì ṣe iṣẹ́ náà.”
11 Tedy oddał Dawid Salomonowi, synowi swemu, wizerunek przysionka, i gmachów jego, i komor jego, i sal jego, i wnętrznych pokojów jego, i domu ubłagalni.
Nígbà náà ni Dafidi fi àpẹẹrẹ fún Solomoni ọmọ rẹ̀ ti ìloro àti ti ilé Olúwa náà, kíkọ́ ọ rẹ̀, àti ti ibi ìṣúra rẹ̀, àti ti iyàrá òkè rẹ̀, àti ti ìyẹ̀wù rẹ̀ àti ti ibùjókòó àánú.
12 Przytem wizerunek wszystkiego, co był umyślił o sieni domu Paćskiego, i o wszystkich gmachach dla skarbów domu Bożego, i dla skarbów rzeczy świętych;
Ó fún un ní àwọn ètò gbogbo èyí tí ẹ̀mí ti fi sí ọkàn rẹ̀ fún ti ààfin ilé Olúwa àti gbogbo yàrá tí ó yíká fún ìṣúra ilé Ọlọ́run àti fún ìṣúra fún ohun yíyà sọ́tọ̀.
13 I dla pocztów kapłańskich, i Lewitów, i dla wszystkiej pracy w usłudze domu Pańskiego, i dla wszystkiego naczynia służby domu Pańskiego.
Ó fún un ní àwọn ìlànà fún ìpín ti àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi àti fún gbogbo iṣẹ́ ìsìn nínú ilé Olúwa àti fún gbogbo ohun èlò tí wọn ó lò nínú ìsìn rẹ̀.
14 Także złota pewną wagę na wszystkie naczynia złote, od wszystkiej usługi; srebra także na wszystkie naczynia srebrne pewną wagę, na wszystkie naczynia ku wszelakiej usłudze;
Ó yàn ìwọ̀n wúrà fún gbogbo ohun èlò wúrà tí a ó lò níbi oríṣìí ìsìn, àti ìwọ̀n fàdákà fún gbogbo ohun èlò fàdákà tí a ó lò fún oríṣìí ìsìn,
15 Mianowicie pewną wagę na świeczniki złote i na lampy ich złote według wagi każdego świecznika i lamp jego, i na świeczniki srebrne według wagi świecznika każdego i lamp jego, według potrzeby każdego świecznika.
ìwọ̀n wúrà fún ìdúró fìtílà àti fìtílà wọn, fún ìwọ̀n fún ọ̀kọ̀ọ̀kan ìdúró fìtílà àti fìtílà wọn; àti ìwọ̀n fàdákà ìdúró fìtílà fàdákà àti àwọn fìtílà rẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìlò ti gbogbo ìdúró fìtílà.
16 Także pewnąwagę złota na stoły chlebów pokładbych, na każdy stół, przytem srebra na stoły srebrne.
Ìwọ̀n ti wúrà fun tábìlì, tábìlì fún àkàrà tí a yà sọ́tọ̀; ìwọ̀n fàdákà fún àwọn tábìlì fàdákà;
17 A na widełki, i na kociołki, i na kadzielnice szczerego złota, i na czasze złote, pewnąwagę na każdą czaszę, i na czasze srebrne, pewną wagę na każdą czaszę.
ìwọ̀n kìkì wúrà fún àwọn àmúga ìjẹun, àwọn ìbùwọ́n ọpọ́n àti àwọn ìkòkò ìpọnmi; ìwọ̀n wúrà fún gbogbo àwopọ̀kọ́ fàdákà;
18 Takżw na ołtarz do kadzeania dał złota szczerego pewną wagę, i złota ku wystawieniu woza Cherubinów, którzyby rozciągnionemi skrzydłami okrywali skrzynię przymierza Pańskiego.
àti ìwọ̀n ìdá wúrà fún pẹpẹ tùràrí ó fún un ní ètò fún kẹ̀kẹ́, ìyẹn ni pé àwọn ìdúró kérúbù wúrà tí wọ́n tan iye wọn ká, wọ́n sì bo àpótí ẹ̀rí Olúwa.
19 To wszystko, rzekł Dawid, opisane z ręki Pańskiej mię doszło, abym zrozumiał wszystko, jako co urobić miano.
“Gbogbo èyí,” ni Dafidi wí pé, “Èmi ní kíkọ sílẹ̀ láti ọwọ́ Olúwa sórí mi, ó sì fún mí ní ìmọ̀ nínú gbogbo iṣẹ́ ètò yìí.”
20 A tak rzekł Dawid do Salomona, syna swego: Zmacniaj się, a bądź mężnym, czyń to; nie bój się, ani się lękaj; bo Pan Bóg, Bóg mój, będzie z tobą, nie opuści cię, ani cię odstąpi, aż dokończysz wszystkiej roboty służby domu Pańskiego.
Dafidi tún sọ fún Solomoni ọmọ rẹ̀ pé, “Jẹ́ alágbára kí o sì gbóyà, kí o sì ṣe iṣẹ́ náà. Má ṣe bẹ̀rù tàbí dààmú, nítorí Olúwa Ọlọ́run, Ọlọ́run mi, wà pẹ̀lú rẹ. Òun kì yóò sì já ọ kule tàbí kọ ọ sílẹ̀ títí gbogbo iṣẹ́ fún ìsìn ní ti ilé Olúwa yóò fi parí.
21 A oto poczty kapłanów i Lewitów do każdej posługi w domu Bożym bądą z tobą w każdej pracy; każdy ochotny i roztropny przy wszelkiej posłudze, także książęta, i wszystek lud staną na każde rozkazanie twoje.
Ìpín àwọn àlùfáà àti àwọn ará Lefi ti ṣetán fún gbogbo iṣẹ́ ilé Olúwa. Gbogbo ọkùnrin tí ó ní ìfẹ́ sí i tí ó sì ní òye oríṣìíríṣìí iṣẹ́. Yóò ràn ọ́ lọ́wọ́ nínú iṣẹ́ náà. Àwọn ìjòyè àti gbogbo àwọn ènìyàn yóò gbọ́rọ̀ sí gbogbo àṣẹ rẹ.”