< I Kronik 2 >

1 Cić są synowie Izraelowi: Ruben, Symeon, Lewi, i Juda, Isaschar i Zabulon,
Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Israẹli. Reubeni, Simeoni, Lefi, Juda, Isakari, Sebuluni,
2 Dan, Józef, i Benjamin, Neftali, Gad i Aser.
Dani, Josẹfu, Benjamini; Naftali, Gadi: àti Aṣeri.
3 Synowie Judy: Her, i Onan, i Sela. Ci trzej urodzili mu się z córki Sui Chananejskiej. Ale Her, pierworodny Judy, był złym przed oczyma Pańskiemi; przetoż go zabił.
Àwọn ọmọ Juda: Eri, Onani àti Ṣela, àwọn mẹ́tẹ̀ẹ̀ta wọ̀nyí ni wọ́n bí fún un láti ọ̀dọ̀ arábìnrin Kenaani, ọmọbìnrin Ṣua. Eri àkọ́bí Juda, ó sì burú ní ojú Olúwa, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa sì pa á.
4 Tamar zasię, niewiastka jego, urodziła mu Faresa i Zarę. Wszystkich synów Judowych pięć.
Tamari, aya ọmọbìnrin Juda, ó sì bí Peresi àti Sera sì ní ọmọ márùn-ún ní àpapọ̀.
5 Synowie Faresowi: Hesron i Hamuel.
Àwọn ọmọ Peresi: Hesroni àti Hamulu.
6 Synowie zaś Zary: Zamry, i Etan, i Heman, i Chalkol, i Darda; wszystkich tych było pięć.
Àwọn ọmọ Sera: Simri, Etani, Hemani, Kalkoli àti Dara, gbogbo wọn jẹ́ márùn-ún.
7 Asynowie Zamrego: Charmi, wnuk Acharowy, który zamięszanie uczynił w Izraelu, zgrzeszywszy kradzieżą rzeczy przeklętych.
Àwọn ọmọ Karmi: Akani, ẹni tí ó mú ìyọnu wá sórí Israẹli nípa ẹ̀ṣẹ̀ ìfibú lórí mímú ohun ìyàsọ́tọ̀.
8 Asynowie Etanowi: Azaryjasz.
Àwọn ọmọ Etani: Asariah.
9 A synowie Esronowi, którzy mu się urodzili: Jerameel, i Ram, i Chalubaj.
Àwọn ọmọ tí a bí fún Hesroni ni: Jerahmeeli, Ramu àti Kalebu.
10 Ale Ram spłodził Aminadaba, a Aminadab spłodził Naasona, książęcia synów Judzkich.
Ramu sì ni baba Amminadabu, àti Amminadabu baba Nahiṣoni olórí àwọn ènìyàn Juda.
11 A Naason spłodził Salmona, a Salmon spłodził Booza.
Nahiṣoni sì ni baba Salmoni, Salmoni ni baba Boasi,
12 A Booz spłodził Obeda, a Obed spłodził Isajego.
Boasi baba Obedi àti Obedi baba Jese.
13 A Isaj spłodził pierworodnego swego Elijaba, i Abinadaba wtórego, i Samma trzeciego.
Jese sì ni baba Eliabu àkọ́bí rẹ̀; ọmọ ẹlẹ́ẹ̀kejì sì ni Abinadabu, ẹlẹ́ẹ̀kẹta ni Ṣimea,
14 Natanaela czwartego, Raddaja piątego.
ẹlẹ́ẹ̀kẹrin Netaneli, ẹlẹ́ẹ̀karùnún Raddai,
15 Ozema szóstego, Dawida siódmego.
ẹlẹ́ẹ̀kẹfà Osemu àti ẹlẹ́ẹ̀keje Dafidi.
16 A siostry ich: Sareija, i Abigail; a synowie Sarwii: Abisaj, i Joab, i Asael, trzej.
Àwọn arábìnrin wọn ni Seruiah àti Abigaili. Àwọn ọmọ mẹ́ta Seruiah ni Abiṣai, Joabu àti Asaheli.
17 A Abigail urodziła Amazę, a ojciec Amazy był Jeter Ismaelczyk.
Abigaili ni ìyá Amasa, ẹni tí baba rẹ̀ sì jẹ́ Jeteri ará Iṣmaeli.
18 A Kaleb, syn Hesronowy, spłodził z Azubą, małżonką swoją, i z Jeryjotą synów. A ci byli synowie jego: Jeser, i Sobab, i Ardon.
Kalebu ọmọ Hesroni ní ọmọ láti ọ̀dọ̀ ìyàwó rẹ̀ Asuba (láti ọ̀dọ̀ Jerioti). Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ọmọ rẹ̀: Jeṣeri, Ṣobabu àti Ardoni.
19 A gdy umarła Azuba, pojął sobie Kaleb Esratę, która mu urodziła Hura.
Nígbà tí Asuba sì kú, Kalebu sì fẹ́ Efrata ní aya, ẹni tí ó bí Huri fún un.
20 A Hur spłodził Ury, a Ury spłodził Besaleela.
Huri ni baba Uri, Uri sì jẹ́ baba Besaleli.
21 Potem wszedł Hesron do córki Machyra, ojca Galaadowego, a pojął ją, będąc w sześćdizesiąt lat; która mu urodziła Seguba.
Nígbà tí ó yá, Hesroni sì dùbúlẹ̀ pẹ̀lú ọmọbìnrin Makiri baba Gileadi (ó sì ti fẹ́ ní aya láti ìgbà tí ó ti wà ní ẹni ọgọ́ta ọdún) ó sì bí Segubu.
22 A Segub spłodził Jaira, który miał dwadzieścia trzy miast w ziemi Galaadskiej.
Segubu sì jẹ́ baba Jairi, ẹni tí ó jẹ́ olùdarí ìlú mẹ́tàlélógún ní ilẹ̀ Gileadi.
23 Bo wziął Giessurytom, i Assyryjczykom wsi Jairowe, i Kanat z miasteczkami jego, sześćdziesiąt miast. To wszystko pobrali synowie Machyra, ojca Galaadowego.
(Ṣùgbọ́n Geṣuri àti Aramu sì fi agbára gba Hafoti-Jairi, àti Kenati pẹ̀lú gbogbo agbègbè rẹ̀ tí wọn tẹ̀dó sí jẹ́ ọgọ́ta ìlú.) Gbogbo wọ̀nyí ni àwọn ọmọ Makiri baba Gileadi.
24 A gdy umarł Hesron w Kaleb Efrata, tedy żona Hesronowa Abija porodziła mu Assura, ojca Tekui.
Lẹ́yìn tí Hesroni sì kú ni Kalebu Efrata, Abijah ìyàwó rẹ̀ ti Hesroni sì bí Aṣihuri baba Tekoa fún un.
25 Byli też synowie Jerameelowi, pierworodnego Hesronowego: Pierworodny Ram, po nim Buana, i Oren, i Osem z Abii.
Ọmọ Jerahmeeli àkọ́bí Hesroni: Ramu ọmọ àkọ́bí rẹ̀ Buna, Oreni, Osemu àti Ahijah.
26 Miał także drugą żonę Jerameel, imieniem Atara; ta jest matka Onamowa.
Jerahmeeli ní ìyàwó mìíràn, ẹni tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Atara; ó sì jẹ́ ìyá fún Onamu.
27 Ale synowie Ramowi, pierworodnego Jerameelowego, byli: Maas, i Jamin, i Achar.
Àwọn ọmọ Ramu àkọ́bí Jerahmeeli: Maasi, Jamini àti Ekeri.
28 Byli też synowie Onamowi: Semaj, i Jada, a synowie Semejego: Nadad i Abisur;
Àwọn ọmọ Onamu: Ṣammai àti Jada. Àwọn ọmọ Ṣammai: Nadabu àti Abiṣuri.
29 A imię żony Abisurowej Abihail, która mu urodziła Achobbana i Molida.
Orúkọ ìyàwó Abiṣuri ni Abihaili ẹni tí ó bí Ahbani àti Molidi.
30 Synowie Nadabowi: Saled i Affaim; lecz Saled umarł bez potomstwa.
Àwọn ọmọ Nadabu Seledi àti Appaimu. Seledi sì kú láìsí ọmọ.
31 A synowie Affaimowi Jesy; a synowie Jesy Sesan, a córka Sesana Achialaj.
Àwọn ọmọ Appaimu: Iṣi, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Ṣeṣani. Ṣeṣani sì jẹ́ baba fún Ahlai.
32 A synowie Jady, brata Semejego, Jeter i Jonatan; ale Jeter umarł bez potomstwa.
Àwọn ọmọ Jada, arákùnrin Ṣammai: Jeteri àti Jonatani. Jeteri sì kú láìní ọmọ.
33 A synowie Jonatanowi: Falet i Zyza. Cić byli synowie Jerameelowi.
Àwọn ọmọ Jonatani: Peleti àti Sasa. Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Jerahmeeli.
34 Lecz nie miał Sesan synów, jedno córki; miał też Sesan sługę Egipczanina, imieniem Jeracha.
Ṣeṣani kò sì ní ọmọkùnrin àwọn ọmọbìnrin nìkan ni ó ní. Ó sì ní ìránṣẹ́ ará Ejibiti tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Jariha.
35 I dał Sesan córkę Jerachowi, słudze swemu, za żonę, która mu urodziła Etaja.
Ṣeṣani sì fi ọmọ obìnrin rẹ̀ ní aya fún ìránṣẹ́ rẹ̀ Jariha, ó sì bí ọmọ fún tí orúkọ rẹ̀ jẹ́ Attai.
36 Etaj spłodził Natana, a Natan spłodził Zabada.
Attai sì jẹ́ baba fún Natani, Natani sì jẹ́ baba fún Sabadi,
37 A Zabad spłodził Efijala, a Efijal spłodził Obeda.
Sabadi ni baba Eflali, Eflali jẹ́ baba Obedi,
38 A obed spłodził Jehu, a Jehu spłodził Azaryjasza.
Obedi sì ni baba Jehu, Jehu ni baba Asariah,
39 A Azaryjasz spłodził Helesa, a Heles spłodził Elasa.
Asariah sì ni baba Helesi, Helesi ni baba Eleasa,
40 A Elas spłodził Sysmaja, a Sysmaj spłodził Selluma.
Eleasa ni baba Sismai, Sismai ni baba Ṣallumu,
41 A Sellum spłodził Ikamijasza, a Ikamijasz spłodził Elisama.
Ṣallumu sì ni baba Jekamiah, Jekamiah sì ni baba Eliṣama.
42 A synowie Kaleba, brata Jerameelowego: Mesa pierworodny jego, który był ojcem Zyfejczyków i synów Maresy, ojca Hebrowowego.
Àwọn ọmọ Kalebu arákùnrin Jerahmeeli: Meṣa àkọ́bí rẹ̀, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Sifi, àti àwọn ọmọ rẹ̀ Meraṣa, ẹni tí ó jẹ́ baba fún Hebroni.
43 A synowie Hebronowi: Kore i Tafua, i Rechem, i Semma.
Àwọn ọmọ Hebroni: Kora, Tapua, Rekemu, àti Ṣema.
44 A Semma spłodził Rahama, syna Jerkaamowego, a Rechem spłodził Sammajego.
Ṣema ni baba Rahamu, Rahamu sì jẹ́ baba fún Jorkeamu. Rekemu sì ni baba Ṣammai.
45 A Sammaj był synem Maonowym, a Maon był ojcem Betsurczyków.
Àwọn ọmọ Ṣammai ni Maoni, Maoni sì ni baba Beti-Suri.
46 Efa też, założnica Kalebowa, urodziła Harana, i Moze, i Giezeza; a Haran spłodził Giezeza.
Efani obìnrin Kalebu sì ni ìyá Harani, Mosa àti Gasesi, Harani sì ni baba Gasesi.
47 A synowie Jachdajowi: Regiem, i Jotam, i Giesan, i Falet, i Efa, i Saaf,
Àwọn ọmọ Jahdai: Regemu, Jotamu, Geṣani, Peleti, Efani àti Ṣaafu.
48 Założnica zaś druga Kalebowa Maacha urodziła Sabera, i Tyrchana.
Maaka obìnrin Kalebu sì ni ìyá Seberi àti Tirhana.
49 A żona Saafowa urodziła ojca Madmeńczyków, i Sewa, ojca Machbeńczyków, i ojca Gabaończyków; a córka Kalebowa była Achsa.
Ó sì bí Ṣaafu baba Madmana, Ṣefa baba Makbena àti baba Gibeah, ọmọbìnrin Kalebu sì ni Aksa.
50 Cić byli synowie Kaleba, syna Hurowego, pierworodnego Efraty: Sobal, ojciec Karyjatyjarymczyków.
Àwọn wọ̀nyí ni ọmọ Kalebu. Àwọn ọmọ Huri, àkọ́bí Efrata: Ṣobali baba Kiriati-Jearimu.
51 Salma, ojciec Betlehemczyków, Charef, ojciec Betgaderczyków.
Salma baba Bẹtilẹhẹmu àti Harefu baba Beti-Gaderi.
52 Miał też synów Sobal, ojciec Karyjatyjarymczyków, który doglądał połowy Menuchoty.
Àwọn ọmọ Ṣobali baba Kiriati-Jearimu ni: Haroe, ìdajì àwọn ará Manaheti.
53 A domy Karyjatyjarymskie były Jetrejczycy, i Futejczycy, i Sematejczycy, i Maserejczycy, z których też poszli Saraitowie, o Estaolitowie.
Àti ìdílé Kiriati-Jearimu: àti àwọn ara Itri, àti àwọn ará Puti, àti àwọn ará Ṣumati àti àwọn ará Miṣraiti: láti ọ̀dọ̀ wọn ni àwọn ọmọ ará Sorati àti àwọn ará Eṣtaoli ti wá.
54 A synowie Salmy: Betlehemczycy, i Netofatczycy, ozdoby domu Joabowego, i połowa Manachaty, ojca Sorygo.
Àwọn ọmọ Salma: Bẹtilẹhẹmu, àti àwọn ará Netofa, Atrotu Beti-Joabu, ìdajì àwọn ará Manahati, àti ará Sori,
55 A domy pisarzów mieszkających w Jabez: Tyryjatejczycy, Symatejczycy, Suchatejczycy. Cić są Cynejczycy, którzy poszli z Hemata, ojca domu Rechabowego.
àti àwọn ìdílé àwọn akọ̀wé, ẹni tí ń gbé ní Jabesi: àti àwọn ọmọ Tirati àti àwọn ará Ṣimeati àti àwọn ará Sukati. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn ará Keni, ẹni tí ó wá láti ọ̀dọ̀ Hamati, baba ilé Rekabu.

< I Kronik 2 >