< زکریا 2 >

در یک رؤیای دیگر مردی را دیدم که چوب اندازه‌گیری در دست داشت. 1
Mó si tún gbé ojú mi, sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ọkùnrin kan ti o mú okùn ìwọ̀n lọ́wọ́ rẹ̀.
پرسیدم: «کجا می‌روی؟» گفت: «می‌روم اورشلیم را اندازه بگیرم، تا ببینم طول و عرضش چیست؟» 2
Mo sí wí pé, “Níbo ni ìwọ ń lọ?” O sí wí fún mí pé, “Láti wọn Jerusalẹmu, láti rí iye ìbú rẹ̀, àti iye gígùn rẹ̀.”
آنگاه فرشته‌ای که با من صحبت می‌کرد جلو رفت تا فرشتهٔ دیگری را که به طرف او می‌آمد استقبال کند. 3
Sì kíyèsi i, angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ jáde lọ, angẹli mìíràn si jáde lọ pàdé rẹ̀.
فرشته دوم به اولی گفت: «بشتاب و به آن مردی که چوب اندازه‌گیری در دست دارد بگو که روزی اورشلیم چنان پر از جمعیت می‌شود که جای کافی برای همه نخواهد بود! بسیاری از مردم با حیواناتشان در خارج از حصار شهر به سر خواهند برد. 4
Ó si wí fún un pé, “Sáré, sọ fún ọ̀dọ́mọkùnrin yìí wí pé, ‘A ó gbé inú Jerusalẹmu bi ìlú ti kò ní odi, nítorí ọ̀pọ̀ ènìyàn àti ohun ọ̀sìn inú rẹ̀.
زیرا خود خداوند برای آنها همچون دیواری آتشین خواهد بود و از ایشان و تمامی اورشلیم مواظبت خواهد نمود. او شکوه و جلال شهر خواهد بود.» 5
Olúwa wí pé: Èmi ó sì jẹ́ odi iná fún un yíká, èmi ó sì jẹ́ ògo láàrín rẹ̀.’
خداوند به قوم خود می‌گوید: «ای کسانی که در بابِل در تبعید هستید، فرار کنید. من شما را به هر سو پراکنده ساختم، ولی دوباره شما را باز می‌گردانم. پس حال، فرار کنید و به اورشلیم بازگردید.» 6
“Wá! Wá! Sá kúrò ni ilẹ̀ àríwá,” ni Olúwa wí, “nítorí pé bí afẹ́fẹ́ mẹ́rin ọ̀run ni mo tú yín káàkiri,” ni Olúwa wí.
7
“Gbà ara rẹ̀ sílẹ̀, ìwọ Sioni, ìwọ tí ó ń bà ọmọbìnrin Babeli gbé.”
خداوند لشکرهای آسمان مرا برگزیده و به مقابله با قومهایی که بر شما ظلم و ستم روا داشته‌اند، فرستاده است. کسی که به شما آزار برساند به خداوند آزار رسانده است، چون شما مثل مردمک چشم خداوند هستید. 8
Nítorí báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Lẹ́yìn ògo rẹ̀ ni a ti rán mi sí àwọn orílẹ̀-èdè tí ń kó yin: nítorí ẹni tí ó tọ́ yin, ó tọ́ ọmọ ojú rẹ̀.
با ایشان خواهم جنگید و ایشان را مغلوب برده‌هایشان خواهم کرد. آنگاه خواهید دانست که خداوند لشکرهای آسمان مرا فرستاده است. 9
Nítorí kíyèsi i, èmi ó gbọn ọwọ́ mi sí orí wọn, wọn yóò sì jẹ́ ìkógun fún ìránṣẹ́ wọn: ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi.
ای اورشلیم، سرود بخوان و شادی کن! چون خداوند می‌فرماید: «می‌آیم تا در میان شما ساکن شوم.» 10
“Kọrin kí o sì yọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni. Nítorí èmi ń bọ̀ àti pé èmi yóò sì gbé àárín rẹ,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
در آن هنگام قومهای زیادی به خداوند ایمان خواهند آورد و آنها هم قوم او خواهند شد و خداوند در میان شما ساکن خواهد گردید. آنگاه خواهید دانست که خداوند لشکرهای آسمان مرا نزد شما فرستاده است. یهودا در سرزمین مقدّس، میراث خداوند خواهد بود، زیرا خداوند بار دیگر اورشلیم را برخواهد گزید تا آن را برکت دهد. 11
“Ọ̀pọ̀lọpọ̀ orílẹ̀-èdè ni yóò dàpọ̀ mọ́ Olúwa ní ọjọ́ náà, wọn yóò sì di ènìyàn mi, èmi yóò sì gbé àárín rẹ, ìwọ yóò sì mọ̀ pé, Olúwa àwọn ọmọ-ogun ni ó rán mi sí ọ.
12
Olúwa yóò sì jogún Juda ìní rẹ̀, ni ilẹ̀ mímọ́, yóò sì tún yan Jerusalẹmu.
ای انسانها، در حضور خداوند خاموش باشید، زیرا او از جایگاه مقدّس خود برخاسته است. 13
Ẹ̀ dákẹ́, gbogbo ẹran-ara níwájú Olúwa: nítorí a jí i láti ibùgbé mímọ́ rẹ̀ wá.”

< زکریا 2 >