< نحمیا 10 >

نحمیای حاکم پسر حَکَلیا، اولین کسی بود که این پیمان را امضا کرد. بعد از او صدقیا، سپس افراد زیر آن را امضا کردند: 1
Àwọn tí ó fi èdìdì dì í ni: Nehemiah baálẹ̀, ọmọ Hakaliah. Sedekiah
کاهنان: سرایا، عزریا، ارمیا، فشحور، امریا، ملکیا، حطوش، شبنیا، ملوک، حاریم، مریموت، عوبدیا، دانیال، جنتون، باروک، مشلام، ابیا، میامین، معزیا، بلجای، شمعیا. 2
Seraiah, Asariah, Jeremiah,
3
Paṣuri, Amariah, Malkiah,
4
Hattusi, Ṣebaniah, Malluki,
5
Harimu, Meremoti, Obadiah,
6
Daniẹli, Ginetoni, Baruku,
7
Meṣullamu, Abijah, Mijamini,
8
Maasiah, Bilgai àti Ṣemaiah. Àwọn wọ̀nyí ni àwọn àlùfáà.
لاویان: یشوع (پسر ازنیا)، بنوی (پسر حیناداد)، قدمی‌ئیل، شبنیا، هودیا، قلیطا، فلایا، حانان، میخا، رحوب، حشبیا، زکور، شربیا، شبنیا، هودیا، بانی، بنینو. 9
Àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua ọmọ Asaniah, Binnui ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Henadadi, Kadmieli,
10
àti àwọn ẹlẹgbẹ́ ẹ wọn: Ṣebaniah, Hodiah, Kelita, Pelaiah, Hanani,
11
Mika, Rehobu, Haṣabiah,
12
Sakkuri, Ṣerebiah, Ṣebaniah,
13
Hodiah, Bani àti Beninu.
سران قوم: فرعوش، فحت موآب، عیلام، زتو، بانی، بونی، عزجد، ببای، ادونیا، بغوای، عودین، عاطیر، حِزِقیا، عزور، هودیا، حاشوم، بیصای، حاریف، عناتوت، نیبای، مجفیعاش، مشلام، حزیر، مشیزبئیل، صادوق، یدوع، فلطیا، حانان، عنایا، هوشع، حننیا، حشوب، هلوحیش، فلحا، شوبیق، رحوم، حشبنا، معسیا، اخیا، حانان، عانان، ملوک، حاریم، بعنه. 14
Àwọn olórí àwọn ènìyàn: Paroṣi, Pahati-Moabu, Elamu, Sattu, Bani,
15
Bunni, Asgadi, Bebai.
16
Adonijah, Bigfai, Adini,
17
Ateri, Hesekiah, Assuri,
18
Hodiah, Haṣumu, Besai,
19
Harifu, Anatoti, Nebai,
20
Magpiaṣi, Meṣullamu, Hesiri
21
Meṣesabeli, Sadoku, Jaddua
22
Pelatiah, Hanani, Anaiah,
23
Hosea, Hananiah, Haṣubu,
24
Halloheṣi, Pileha, Ṣobeki,
25
Rehumu, Haṣabna, Maaseiah,
26
Ahijah, Hanani, Anani,
27
Malluki, Harimu, àti Baanah.
ما مردم اسرائیل، کاهنان، لاویان، نگهبانان، دسته سرایندگان، خدمتگزاران خانهٔ خدا، و تمام کسانی که با زنان، پسران و دختران بالغ خویش که با اطاعت از تورات خدا، خود را از قومهای بیگانه جدا کرده‌ایم، 28
“Àwọn ènìyàn tókù—àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi, àwọn aṣọ́nà, àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti gbogbo àwọn tí wọ́n ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn àjèjì nítorí òfin Ọlọ́run, papọ̀ pẹ̀lú ìyàwó wọn, gbogbo ọmọkùnrin àti àwọn ọmọbìnrin wọn, tí òye yé
به این وسیله با برادران و سران قوم خود متحد شده، قسم می‌خوریم که دستورهای خدا را که توسط خدمتگزارش موسی داده شد اطاعت کنیم؛ و اگر از احکام و اوامر او سرپیچی کنیم لعنت خدا بر ما باشد. 29
gbogbo wọn fi ara mọ́ àwọn arákùnrin wọn, àwọn ọlọ́lá, wọ́n sì fi ègún àti ìbúra dé ara wọn láti máa tẹ̀lé òfin Ọlọ́run tí a fi fún wọn ní ipasẹ̀ Mose ìránṣẹ́ Ọlọ́run àti láti pa gbogbo àṣẹ, ìlànà àti òfin Olúwa, wa mọ́ dáradára.
قول می‌دهیم که نه دختران خود را به پسران غیریهودی بدهیم و نه بگذاریم پسران ما با دختران غیریهودی ازدواج کنند. 30
“A ti ṣe ìlérí pé, a kò ní fi àwọn ọmọbìnrin wa fún àwọn tí wọ́n wà ní àyíká wa bí ìyàwó, tàbí fẹ́ àwọn ọmọbìnrin wọn fún àwọn ọmọkùnrin wa.
همچنین قول می‌دهیم که اگر قومهای بیگانه در روز شَبّات یا در یکی از روزهای مقدّس دیگر بخواهند به ما غله یا چیز دیگری بفروشند، از ایشان نخریم و هر هفت سال یک بار چیزی در زمین نکاریم و قرض برادران یهودی خود را ببخشیم. 31
“Nígbà tí àwọn ènìyàn àdúgbò bá mú ọjà tàbí oúnjẹ wá ní ọjọ́ ìsinmi láti tà, àwa kò ní rà á ní ọwọ́ wọn ní ọjọ́ ìsinmi tàbí ní ọjọ́ mímọ́ kankan. Ní gbogbo ọdún keje àwa kò ní ro ilẹ̀ náà, a ó sì pa gbogbo àwọn gbèsè rẹ́.
عهد می‌بندیم که هر سال هر یک از ما یک سوم مثقال نقره برای مخارج خانهٔ خدا تقدیم کنیم، 32
“Àwa gbà ojúṣe láti máa pa àṣẹ mọ́ pé, a ó máa san ìdámẹ́ta ṣékélì ní ọdọọdún fún iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa:
یعنی برای نان حضور، هدیهٔ آردی و قربانیهای سوختنی روزانه، قربانیهای روزهای شَبّات و جشنهای ماه نو و جشنهای سالیانه، هدایای مقدّس دیگر، قربانی گناه برای کفاره قوم اسرائیل، و برای تمام خدمات خانهٔ خدای ما. 33
nítorí oúnjẹ tí ó wà lórí tábìlì; nítorí ọrẹ ohun jíjẹ àti ẹbọ sísun ìgbà gbogbo; nítorí ọrẹ ọjọ́ ìsinmi, ti àyajọ́ oṣù tuntun àti àjọ̀dún tí a yàn; nítorí ọrẹ mímọ́; nítorí ọrẹ ẹ̀ṣẹ̀ láti ṣe ètùtù fún Israẹli; àti fún gbogbo iṣẹ́ ilé Ọlọ́run wa.
ما کاهنان، لاویان و مردم قول می‌دهیم که مطابق دستور تورات، هیزم مورد نیاز مذبح خانهٔ خداوند، خدایمان را تهیه کنیم و هر سال قرعه خواهیم انداخت تا معلوم شود چه قبیله‌ای باید این کار را انجام دهد. 34
“Àwa, àwọn àlùfáà, àwọn ọmọ Lefi àti àwọn ènìyàn náà ti dìbò láti pinnu ìgbà tí olúkúlùkù àwọn ìdílé yóò mú ọrẹ igi wá láti sun lọ́ríi pẹpẹ Olúwa Ọlọ́run wa sí ilé Ọlọ́run wa, ní àkókò tí a yàn ní ọdọọdún. Gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin.
قول می‌دهیم نوبر غله و میوهٔ خود را هر سال به خانهٔ خداوند بیاوریم. 35
“Àwa tún gbà ojúṣe láti mú àkọ́so àwọn èso wa wá àti gbogbo èso igi wá ní ilé Olúwa.
قول می‌دهیم که پسران ارشد و تمام نخست‌زاده‌های گله و رمه خود را مطابق دستور تورات به خانهٔ خدای خود بیاوریم و به دست کاهنانی که در آنجا خدمت می‌کنند بسپاریم. 36
“Gẹ́gẹ́ bí a sì ti kọ ọ́ sínú ìwé òfin, àwa yóò mú àkọ́bí àwọn ọmọkùnrin wa, ti ohun ọ̀sìn wa, ti àwọn abo màlúù àti ti àwọn àgùntàn wa, wá sí ilé Ọlọ́run wa, fún àwọn àlùfáà tí ń ṣiṣẹ́ níbẹ̀.
همچنین قول می‌دهیم خمیری را که از نوبر غله تهیه می‌کنیم همراه نوبر انواع میوه‌ها و نوبر شراب تازه و روغن زیتون خود به کاهنانی که در خانهٔ خدا هستند بدهیم. ما ده‌یک تمام محصولات زمین خود را به لاویانی که در روستاهای ما مسئول جمع‌آوری ده‌یک هستند خواهیم داد. 37
“Síwájú sí i, àwa yóò mú àkọ́so oúnjẹ ilẹ̀ wa ti ọrẹ oúnjẹ, ti gbogbo èso àwọn igi àti ti wáìnì tuntun wa àti ti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí ilé Ọlọ́run wa àti fún àwọn àlùfáà. Àwa yóò sì mú ìdámẹ́wàá ohun ọ̀gbìn wá fún àwọn ọmọ Lefi, nítorí àwọn ọmọ Lefi ni ó ń gba ìdámẹ́wàá ní gbogbo àwọn ìlú tí a ti ń ṣiṣẹ́.
در وقت جمع‌آوری ده‌یک، کاهنی (که از نسل هارون است) همراه لاویان خواهد بود و لاویان یک دهم از ده‌یکها را به خانۀ خدای ما خواهند آورد و آنجا انبار خواهند کرد. 38
Àlùfáà tí o ti ìdílé Aaroni wá ni yóò wá pẹ̀lú àwọn ọmọ Lefi nígbà tí wọ́n bá ń gba ìdámẹ́wàá, àwọn ọmọ Lefi yóò sì mú ìdámẹ́wàá ti ìdámẹ́wàá náà wá sí ilé Ọlọ́run, sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí inú ilé ìṣúra.
ما مردم اسرائیل و لاویان، این هدایای غله، شراب تازه و روغن زیتون را به خانۀ خدا خواهیم آورد و در اتاقهایی که وسایل خانهٔ خدا نگهداری می‌شود و کاهنان، نگهبانان و سرایندگان در آنجا زندگی می‌کنند، انبار خواهیم کرد. قول می‌دهیم که از خانهٔ خدا غافل نشویم. 39
Àwọn ènìyàn Israẹli, àti àwọn ọmọ Lefi gbọdọ̀ mú ọrẹ oúnjẹ, wáìnì tuntun àti òróró wá sí yàrá ìkó nǹkan pamọ́ sí níbi tí a pa ohun èlò ibi mímọ́ mọ́ sí àti ibi tí àwọn àlùfáà tí ń ṣe ìránṣẹ́ lọ́wọ́, àwọn aṣọ́nà àti àwọn akọrin máa ń dúró sí. “Àwa kì yóò gbàgbé tàbí ṣe àìbìkítà nípa ilé Ọlọ́run wa.”

< نحمیا 10 >