< اشعیا 18 >
در آن سوی رودخانههای حبشه سرزمینی هست که قایقهای بادبانی در آبهایش رفت و آمد میکنند. | 1 |
Ègbé ni fún ilẹ̀ tí ó kún fún ariwo ìyẹ́ eṣú, ní àwọn ipadò Kuṣi,
سرزمینی که سفیران خود را بر قایقهایی ساخته شده از نی، به رود نیل میفرستد. ای سفیران تندرو به آن سرزمینی بروید که بین رودخانهها است و قومی بلند بالا و نیرومند در آن زندگی میکنند قومی که همه جا خوف و هراس ایجاد کردهاند. | 2 |
tí ó rán àwọn ikọ̀ lórí Òkun lórí omi nínú ọkọ̀-ọpọ́n tí a fi eèsún papirusi ṣe. Ẹ lọ, ẹ̀yin ikọ̀ tí ó yára, sí àwọn ènìyàn gíga tí àwọ̀ ara wọn jọ̀lọ̀, sí àwọn ènìyàn tí a ń bẹ̀rù káàkiri, orílẹ̀-èdè aláfojúdi alájèjì èdè, tí odò pín ilẹ̀ rẹ̀ yẹ́lẹyẹ̀lẹ.
ای مردم دنیا توجه کنید! به پرچمی که بر قلهٔ کوهها برافراشته میشود بنگرید و به صدای شیپوری که برای جنگ نواخته میشود گوش دهید! | 3 |
Gbogbo ẹ̀yin ènìyàn ayé, tí ó ń gbé orílẹ̀ ayé, nígbà tí a bá gbé àsíá kan sókè lórí òkè, ẹ ó rí i, nígbà tí a bá fun fèrè kan ẹ ó gbọ́ ọ.
خداوند به من چنین فرموده است: «من از مکان خود به آرامی نظر خواهم کرد، به آرامی یک روز باصفای تابستانی و یک صبح دلپذیر پائیزی در وقت حصاد.» | 4 |
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Èmi yóò dákẹ́ jẹ́ẹ́, èmi yóò sì máa wo òréré láti ibùgbé e mi wá, gẹ́gẹ́ bí ooru gbígbóná nínú ìtànṣán oòrùn, gẹ́gẹ́ bí òjò-dídì ní àárín gbùngbùn ìkórè.”
زیرا پیش از این که حصاد را جمع کنند، درست پس از ریخته شدن شکوفهها و رسیدن انگور، حبشه مانند درخت انگوری که شاخههایش را با اره بریده باشند، نابود خواهد شد. | 5 |
Nítorí, kí ìkórè tó bẹ̀rẹ̀, nígbà tí ìrudí bá kún, nígbà tí ìtànná bá di èso àjàrà pípọ́n. Òun yóò sì fi dòjé rẹ́ ẹ̀ka tuntun, yóò sì mu kúrò, yóò sì gé ẹ̀ka lulẹ̀.
سربازان حبش در صحرا خواهند مرد و اجسادشان برای پرندگان شکاری و حیوانات وحشی واگذاشته خواهد شد. پرندگان شکاری در تابستان، و حیوانات وحشی در زمستان، از لاشههای آنها تغذیه خواهند کرد. | 6 |
A ó fi wọ́n sílẹ̀ fún àwọn ẹyẹ òkè ńlá àti fún àwọn ẹranko búburú; àwọn ẹyẹ yóò fi wọ́n ṣe oúnjẹ nínú ẹ̀ẹ̀rùn àti àwọn ẹranko búburú nígbà òjò.
اما زمانی خواهد رسید که این قوم قدبلند و نیرومند که همه جا خوف و هراس ایجاد میکردند و سرزمینشان میان رودخانهها بود به اورشلیم که خداوند لشکرهای آسمان نام خود را در آن قرار داده است خواهند آمد و برای او هدیه خواهند آورد. | 7 |
Ní àkókò náà ni a ó mú ẹ̀bùn wá fún Olúwa àwọn ọmọ-ogun láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn gíga tí ẹran-ara wọn jọ̀lọ̀, láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn tí a bẹ̀rù níbi gbogbo, orílẹ̀-èdè aláfojúdi àti alájèjì èdè, ilẹ̀ ẹni tí omi pín sí yẹ́lẹyẹ̀lẹ— a ó mú àwọn ẹ̀bùn náà wá sí òkè Sioni, ibi tí orúkọ Olúwa àwọn ọmọ-ogun gbé wà.