< Izililo 1 >
1 Yeka ukuhlala kodwa komuzi owawugcwele abantu! Usunjengomfelokazi owawumkhulu phakathi kwezizwe, owawuyinkosikazi phakathi kwezabelo usuyisibhalwa!
Báwo ni ìlú ṣe jókòó nìkan, nígbà kan tí ó sì kún fún ènìyàn! Ó ti fìgbà kan jẹ́ ìlú olókìkí láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, tí ó wà ní ipò opó, ẹni tí ó jẹ́ ọmọ ọbabìnrin láàrín ìlú ni ó padà di ẹrú.
2 Uyakhala lokukhala inyembezi ebusuku, lezinyembezi zawo zisezihlathini zawo. Kawulamduduzi phakathi kwazo zonke izithandwa zawo. Bonke abangane bawo bawuphethe ngenkohliso, sebeyizitha zawo.
Ọ̀gànjọ́ òru ni ó fi máa ń sọkún kíkorò pẹ̀lú omijé ní ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀ tí ó dúró sí ẹ̀rẹ̀kẹ́ rẹ̀. Nínú gbogbo àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kò sí ọ̀kan nínú wọn láti rẹ̀ ẹ́ lẹ́kún. Gbogbo àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ ti jọ̀wọ́ rẹ̀ wọ́n ti di alátakò rẹ̀.
3 UJuda useye ekuthunjweni ngenxa yokuhlupheka langenxa yobukhulu bobugqili; yena uhlala phakathi kwabezizwe, katholi ukuphumula; bonke abamzingelayo bamfica ephakathi kwezimbandezelo.
Lẹ́yìn ìjìyà àti ìpọ́njú nínú oko ẹrú, Juda lọ sí àjò Ó tẹ̀dó láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n kò rí ibi ìsinmi. Àwọn tí ó ń tẹ̀lé ká á mọ́ ibi tí kò ti le sá àsálà.
4 Indlela zeZiyoni ziyalila, ngoba kungekho ozayo emkhosini omisiweyo; wonke amasango ayo angamanxiwa; abapristi bayo bayabubula, izintombi zayo ezimsulwa zidabukile, layo isekubabeni.
Gbogbo ọ̀nà tí ó wọ Sioni ń ṣọ̀fọ̀, nítorí ẹnìkan kò wá sí àjọ̀dún tí a yàn. Gbogbo ẹnu-bodè rẹ̀ dahoro, àwọn àlùfáà rẹ̀ kẹ́dùn, àwọn wúńdíá rẹ̀ sì ń káàánú, òun gan an wà ní ọkàn kíkorò.
5 Abamelani bayo sebeyinhloko, izitha zayo zonwabile; ngoba iNkosi iyidabulile ngenxa yobunengi beziphambeko zayo; abantwana bayo sebeye ekuthunjweni phambi kwesitha.
Àwọn aninilára rẹ̀ gbogbo di olúwa rẹ̀, nǹkan sì rọrùn fún àwọn ọ̀tá rẹ̀, Olúwa ti fún un ní ìjìyà tó tọ́ nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀. Àwọn ẹ̀ṣọ́ wẹ́wẹ́ rẹ̀ lọ sí oko ẹrú, ìgbèkùn níwájú àwọn ọ̀tá.
6 Labo bonke ubuhle bayo busukile kundodakazi yeZiyoni. Iziphathamandla zayo zinjengezindluzele ezingatholi idlelo, njalo ziyahamba zingelamandla phambi komzingeli.
Gbogbo ẹwà ti di ohun ìgbàgbé kúrò lọ́dọ̀ ọmọbìnrin Sioni. Àwọn ìjòyè rẹ̀ dàbí i àgbọ̀nrín tí kò rí ewé tútù jẹ; nínú àárẹ̀ wọ́n sáré níwájú ẹni tí ó ń lé wọn.
7 Ezinsukwini zenhlupheko yayo lokuzulazula kwayo iJerusalema yakhumbula zonke izinto zayo eziloyisekayo okwakukhona kusukela ezinsukwini zasendulo, lapho abantu bayo bawela esandleni sesitha, njalo ingelamsizi; izitha zayibona, zahleka usulu amasabatha ayo.
Ní ọjọ́ ìpọ́njú àti àrìnká rẹ̀ ni Jerusalẹmu rántí àwọn ohun ìní dáradára rẹ̀ tí ó jẹ́ tirẹ̀ ní ọjọ́ pípẹ́. Nígbà tí àwọn ènìyàn rẹ̀ ṣubú ṣọ́wọ́ àwọn ọ̀tá, kò sì ṣí olùrànlọ́wọ́ fún un. Àwọn ọ̀tá rẹ̀ wò ó wọ́n sì ń fi ìparun rẹ̀ ṣẹlẹ́yà.
8 IJerusalema yonile kakhulu, ngakho-ke isingcolile; bonke ababeyihlonipha bayidelela, ngoba sebebonile ubuze bayo; yona isibubula, ibuyele emuva.
Jerusalẹmu sì ti dẹ́ṣẹ̀ púpọ̀ ó sì ti di aláìmọ́. Àwọn tí ó ń tẹríba fún un sì kẹ́gàn rẹ̀, nítorí wọ́n ti rí ìhòhò rẹ̀; ó kérora fúnra rẹ̀, ó sì lọ kúrò.
9 Ukungcola kwayo kwakusemiphethweni yezigqoko zayo; kayikhumbulanga ukucina kwayo; ngakho yehla ngokumangalisayo, yayingelamduduzi. Nkosi, bona inhlupheko yami, ngoba isitha sizikhulisile.
Ìdọ̀tí wà ní etí aṣọ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò wo ọjọ́ iwájú rẹ̀. Ìṣubú rẹ̀ ya ni lẹ́nu; olùtùnú kò sì ṣí fún un. “Wo ìpọ́njú mi, Olúwa, nítorí àwọn ọ̀tá ti borí.”
10 Isitha selule isandla saso phezu kwazo zonke izinto zayo eziloyisekayo; ngoba ibonile izizwe zingena endaweni yayo engcwele, owazilaya ukuthi zingangeni phakathi kwebandla lakho.
Ọ̀tá ti gbọ́wọ́ lé gbogbo ìní rẹ; o rí pé àwọn orílẹ̀-èdè tí wọ́n wọ ibi mímọ́ rẹ— àwọn tí o ti kọ̀sílẹ̀ láti wọ ìpéjọpọ̀ rẹ.
11 Bonke abantu bayo bayabubula, bedinga isinkwa; banike izinto zabo eziloyisekayo ngokudla ukuthi bavuselele umphefumulo. Bona, Nkosi, ukhangele, ngoba ngiyadelelwa.
Àwọn ènìyàn rẹ̀ ń kérora bí wọ́n ti ń wá oúnjẹ; wọ́n fi ohun ìní wọn ṣe pàṣípàrọ̀ oúnjẹ láti mú wọn wà láààyè. “Wò ó, Olúwa, kí o sì rò ó, nítorí a kọ̀ mí sílẹ̀.”
12 Kakusilutho kini yini lonke elidlulayo ngendlela? Khangelani libone uba kukhona yini usizi njengosizi lwami, olwenziwe kimi, iNkosi engidabule ngalo osukwini lokuvutha kolaka lwayo.
“Kò ha jẹ́ nǹkan kan sí i yín? Gbogbo ẹ̀yin tí ń rékọjá. Ǹjẹ́ ẹnìkan ń jìyà bí èmi ti ń jìyà tí a fi fún mi, ti Olúwa mú wá fún mi ní ọjọ́ ìbínú gbígbóná rẹ̀.
13 Iphezulu, ithumele umlilo emathanjeni ami, wawehlula; ithiyele unyawo lwami imbule, ingibuyisele emuva; ingenze ngaba lunxiwa, ngaphela amandla usuku lonke.
“Ó rán iná láti òkè sọ̀kalẹ̀ sínú egungun ara mi. Ó dẹ àwọ̀n fún ẹsẹ̀ mi, ó sì yí mi padà. Ó ti pa mí lára mó ń kú lọ ní gbogbo ọjọ́.
14 Ijokwe leziphambeko zami libotshwe ngesandla sayo; zelukiwe, zenyukele entanyeni yami, iwisile amandla ami; iNkosi inginikele ezandleni zabo, ngingelakho ukuvuka.
“Ẹ̀ṣẹ̀ mi ti di sísopọ̀ sí àjàgà; ọwọ́ rẹ̀ ni a fi hun ún papọ̀. Wọ́n ti yí ọrùn mi ká Olúwa sì ti dín agbára mi kù. Ó sì ti fi mí lé àwọn tí n kò le dojúkọ lọ́wọ́.
15 INkosi yeyisile wonke amaqhawe ami phakathi kwami; yabiza umhlangano omelene lami ukuchoboza amajaha ami; iNkosi inyathelele intombi emsulwa, indodakazi yakoJuda, isikhamelo sewayini.
“Olúwa kọ àwọn akọni mi sílẹ̀, ó rán àwọn ológun lòdì sí mi kí wọn pa àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin mi run. Nínú ìfúntí wáìnì rẹ̀ Olúwa tẹ́ àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin Juda.
16 Ngenxa yalezizinto ngiyakhala inyembezi; ilihlo lami, ilihlo lami lehlisa amanzi, ngoba umduduzi obengavuselela umphefumulo wami ukhatshana lami; abantwana bami bachithakele ngoba isitha sinqobile.
“Ìdí nìyí tí mo fi ń sọkún tí omijé sì ń dà lójú mi. Olùtùnú àti ẹni tí ó le mú ọkàn mi sọjí jìnnà sí mi, kò sí ẹni tí yóò dá ẹ̀mí mi padà. Àwọn ọmọ mi di aláìní nítorí ọ̀tá ti borí.”
17 IZiyoni iyelula izandla zayo, kakho oyiduduzayo. INkosi ilayile ngoJakobe ukuthi abamzingelezeleyo babe yizitha zakhe. IJerusalema injengowesifazana ongcolileyo phakathi kwabo.
Sioni na ọwọ́ jáde, ṣùgbọ́n kò sí olùtùnú fún un. Olúwa ti pàṣẹ fún Jakọbu pé àwọn ará ilé rẹ̀ di ọ̀tá fún un Jerusalẹmu ti di ohun aláìmọ́ láàrín wọn.
18 INkosi ilungile, ngoba ngivukele umlomo wayo. Ake lizwe, bantu lonke, libone usizi lwami. Intombi zami ezimsulwa lamajaha ami baye ekuthunjweni.
“Olóòtítọ́ ni Olúwa, ṣùgbọ́n mo ṣọ̀tẹ̀ sí àṣẹ rẹ̀. Ẹ gbọ́, gbogbo ènìyàn; ẹ wò mí wò ìyà mi. Gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin àti ọ̀dọ́mọbìnrin mi ni a ti kó lọ sí ìgbèkùn.
19 Ngabiza izithandwa zami, kodwa zona zangikhohlisa. Abapristi bami labadala bami baphefumula okokucina emzini, besazidingela ukudla ukuze bavuselele umphefumulo wabo.
“Mo pe àwọn ọ̀rẹ́ mi ṣùgbọ́n wọ́n dà mí. Àwọn olórí àlùfáà àti àgbàgbà mi ṣègbé sínú ìlú nígbà tí wọ́n ń wá oúnjẹ tí yóò mú wọn wà láààyè.
20 Bona, Nkosi, ngoba ngilusizi; imibilini yami idungekile, inhliziyo yami iphendukile phakathi kwami, ngoba ngaba lenkani kakhulu. Ngaphandle inkemba iyemuka abantwana, endlini kunjengokufa.
“Olúwa, wò ó, bí mo ti wà nínú ìnira! Tí mo sì ń jẹ̀rora nínú mi, ìdààmú dé bá ọkàn mi nítorí pé a ti ṣọ̀tẹ̀ sí mi gidigidi. Ní gbangba ni idà ń parun; ikú wà nínú ilé pẹ̀lú.
21 Bezwile ukuthi mina ngiyabubula; kangilamduduzi; zonke izitha zami zizwile ngobubi bami; ziyathokoza ngoba wena ukwenzile. Uzalufikisa usuku osulumemezile, khona zizakuba njengami.
“Àwọn ènìyàn ti gbọ́ ìrora mi, ṣùgbọ́n kò sí olùtùnú fún mi. Àwọn ọ̀tá mi ti gbọ́ ìparun mi; wọ́n yọ̀ sí ohun tí o ṣe. Kí o mú ọjọ́ tí o ti kéde, kí wọ́n le dàbí tèmi.
22 Kabufike bonke ububi bazo phambi kwakho, wenze kizo njengalokhu wenzile kimi ngenxa yazo zonke iziphambeko zami; ngoba ukububula kwami kunengi, lenhliziyo yami iphela amandla.
“Jẹ́ kí ìwà ìkà wọn wá síwájú rẹ; jẹ wọ́n ní yà bí o ṣe jẹ mí ní yà nítorí gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ mi. Ìrora mi pọ̀ ọkàn mi sì rẹ̀wẹ̀sì.”