< 1 Amakhosi 21 >

1 Kwasekusithi emva kwalezizinto uNabothi umJizereyeli wayelesivini esasiseJizereyeli phansi kwesigodlo sikaAhabi inkosi yeSamariya.
Ó sì ṣe lẹ́yìn nǹkan wọ̀nyí Naboti ará Jesreeli sì ní ọgbà àjàrà kan ní Jesreeli, ní ẹ̀gbẹ́ ààfin Ahabu ọba Samaria.
2 UAhabi wasekhuluma loNabothi esithi: Ngipha isivini sakho ukuze sibe kimi yisivande semibhida, ngoba siseduze phansi kwendlu yami; ngizakunika isivini esingcono kulaso esikhundleni saso; uba kukuhle emehlweni akho, ngizakunika imali ngentengo yaso.
Ahabu sì wí fún Naboti pé, “Fún mi ní ọgbà àjàrà rẹ, kí èmi kí ó fi ṣe ọgbà-ewébẹ̀, nítorí tí ó súnmọ́ tòsí ilé mi, èmi yóò sì fún ọ ní ọgbà àjàrà tí ó sàn jù ú lọ dípò rẹ̀; tàbí bí ó bá sì dára ní ojú rẹ, èmi yóò fi iye owó rẹ̀ fún ọ.”
3 Kodwa uNabothi wathi kuAhabi: Kakube khatshana lami ngeNkosi ukuthi ngikunike ilifa labobaba.
Ṣùgbọ́n Naboti wí fún Ahabu pé, “Olúwa má jẹ́ kí èmi fi ogún àwọn baba mi fún ọ.”
4 UAhabi wasengena endlini yakhe enyukumele ethukuthele ngenxa yelizwi uNabothi umJizereyeli ayelikhulume kuye, ngoba wayethe: Kangiyikukunika ilifa labobaba. Wasecambalala embhedeni wakhe, waphendula ubuso bakhe, kadlanga ukudla.
Ahabu sì wá sí ilé rẹ̀, ó wugbọ́, inú rẹ̀ sì bàjẹ́ nítorí ọ̀rọ̀ tí Naboti ará Jesreeli sọ fún un; nítorí tí ó wí pé, “Èmi kì yóò fún ọ ní ogún àwọn baba mi.” Ó sì dùbúlẹ̀ lórí ibùsùn rẹ̀, ó sì yí ojú rẹ̀ padà, kò sì fẹ́ jẹun.
5 UJezebeli umkakhe wasesiza kuye wathi kuye: Kungani umoya wakho usineme ukuze ungadli ukudla?
Jesebeli aya rẹ̀ sì tọ̀ ọ́ wá, ó sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Èéṣe tí inú rẹ fi bàjẹ́, èéṣe tí ìwọ kò sì jẹun?”
6 Wasesithi kuye: Ngoba ngikhulume loNabothi umJizereyeli ngithe kuye: Nginike isivini sakho ngemali, loba uba uthanda ngizakunika isivini esikhundleni saso; wasesithi: Kangiyikukunika isivini sami.
Ó sì dá a lóhùn pé, “Nítorí tí mo wí fún Naboti ará Jesreeli pé, ‘Ta ọgbà àjàrà rẹ fún mi, tàbí bí ó bá wù ọ́, èmi yóò fún ọ ní ọgbà àjàrà mìíràn ní ipò rẹ̀.’ Ṣùgbọ́n ó wí pé, ‘Èmi kì yóò fún ọ ní ọgbà àjàrà mi.’”
7 UJezebeli umkakhe wasesithi kuye: Khathesi nguwe obusa umbuso wakoIsrayeli? Vuka udle isinkwa, lenhliziyo yakho ithokoze; ngizakunika mina isivini sikaNabothi umJizereyeli.
Jesebeli aya rẹ̀ sì wí pé, “Ṣé báyìí ni ìwọ yóò ṣe ṣe bí ọba lórí Israẹli? Dìde, jẹun! Kí o sì jẹ́ kí inú rẹ̀ dùn. Èmi yóò sì fún ọ ní ọgbà àjàrà Naboti ará Jesreeli.”
8 Wasebhala izincwadi ngebizo likaAhabi, wazidinda ngophawu lwakhe, wazithumela izincwadi ebadaleni lakuzikhulu, ababesemzini wakhe, behlala loNabothi.
Bẹ́ẹ̀ ni ó kọ̀wé ní orúkọ Ahabu, ó sì fi èdìdì rẹ̀ dì í, ó sì fi ìwé náà ránṣẹ́ sí àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́lá tí ó ń gbé ní ìlú Naboti pẹ̀lú rẹ̀.
9 Wasebhala ezincwadini esithi: Memezelani izilo lokudla, limhlalise uNabothi ngaphezulu kwabantu;
Nínú àwọn ìwé náà, ó kọ pé, “Ẹ kéde àwẹ̀, kí ẹ sì fi Naboti sí ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn.
10 beselihlalisa amadoda amabili, amadodana kaBheliyali, maqondana laye ukuthi afakaze emelene laye esithi: Uthuke uNkulunkulu lenkosi. Beselimkhuphela phandle limkhande ngamatshe aze afe.
Ṣùgbọ́n kí ẹ fi ènìyàn méjì, ẹni búburú síwájú rẹ̀ láti jẹ́rìí sí i wí pé, ó bú Ọlọ́run àti ọba. Nígbà náà ni kí ẹ mú u jáde, kí ẹ sì sọ ọ́ ní òkúta pa.”
11 Lamadoda alumuzi wakhe, abadala lezikhulu ababehlala emzini wakhe, benza njengokuthumela kukaJezebeli kuwo, njengokubhalwe ezincwadini ayewathumele zona.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn àgbàgbà àti àwọn ọlọ́lá tí wọ́n ń ṣe ará ìlú Naboti sì ṣe gẹ́gẹ́ bí ìwé tí Jesebeli kọ ránṣẹ́ sí wọn.
12 Amemezela izilo lokudla, ahlalisa uNabothi phezulu kwabantu.
Wọ́n sì kéde àwẹ̀, wọ́n sì fi Naboti sí ipò ọlá láàrín àwọn ènìyàn.
13 Asengena amadoda amabili, amadodana kaBheliyali, ahlala maqondana laye; lamadoda kaBheliyali afakaza emelene laye, emelene loNabothi, phambi kwabantu, esithi: UNabothi uthuke uNkulunkulu lenkosi. Basebemkhuphela ngaphandle komuzi, bamkhanda ngamatshe waze wafa.
Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọkùnrin méjì sì dé, àwọn ẹni búburú, wọ́n sì jókòó síwájú rẹ̀, wọ́n sì jẹ́rìí lòdì sí Naboti níwájú àwọn ènìyàn wí pé, “Naboti ti bú Ọlọ́run àti ọba.” Nígbà náà ni wọ́n mú jáde kúrò ní ìlú, wọ́n sì sọ ọ́ ní òkúta pa.
14 Basebethumela kuJezebeli besithi: UNabothi usekhandwe ngamatshe wafa.
Nígbà náà ni wọ́n ránṣẹ́ sí Jesebeli wí pé, “A ti sọ Naboti ní òkúta, ó sì kú.”
15 Kwasekusithi uJezebeli esezwile ukuthi uNabothi usekhandwe ngamatshe wafa, uJezebeli wathi kuAhabi: Vuka uthathe isivini sikaNabothi umJizereyeli sibe ngesakho, ala ukukunika sona ngemali, ngoba uNabothi kaphili, kodwa ufile.
Bí Jesebeli sì ti gbọ́ pé, a ti sọ Naboti ní Òkúta pa, ó sì wí fún Ahabu pé, “Dìde! Kí o sì jogún ọgbà àjàrà Naboti, ará Jesreeli, tí ó kọ̀ láti tà fún ọ kò sí láààyè mọ́, ó ti kú.”
16 Kwasekusithi uAhabi esezwile ukuthi uNabothi ufile, uAhabi wasukuma ukwehlela esivinini sikaNabothi umJizereyeli, ukusithatha sibe ngesakhe.
Nígbà tí Ahabu sì gbọ́ pé Naboti ti kú, ó sì dìde, ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún ọgbà àjàrà Naboti.
17 Kwasekufika ilizwi leNkosi kuElija umTishibi lisithi:
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah ará Tiṣibi wá wí pé,
18 Sukuma wehle ukuhlangabeza uAhabi inkosi yakoIsrayeli, oseSamariya; khangela, usesivinini sikaNabothi, ehlele khona ukuze asithathe sibe ngesakhe.
“Sọ̀kalẹ̀ lọ láti lọ pàdé Ahabu ọba Israẹli, tí ó wà ní Samaria. Ó wà ní ọgbà àjàrà Naboti báyìí, níbi tí ó sọ̀kalẹ̀ lọ láti jogún rẹ̀.
19 Uzakhuluma kuye uthi: Itsho njalo iNkosi: Ubulele futhi wathatha yini kwaba ngokwakho? Njalo uzakhuluma kuye uthi: Itsho njalo iNkosi: Endaweni lapho izinja ezikhothe khona igazi likaNabothi, izinja zizakhotha igazi lakho, ngitsho elakho.
Sọ fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí: Ǹjẹ́ ìwọ kò ti pa ènìyàn, o sì ti fi agbára gba ogún rẹ̀?’ Nígbà náà ni kí o wí fún un pé, ‘Báyìí ni Olúwa wí: Níbi tí ajá gbé lá ẹ̀jẹ̀ Naboti, ni àwọn ajá yóò lá ẹ̀jẹ̀ rẹ, àní tìrẹ!’”
20 UAhabi wasesithi kuElija: Ungificile yini, sitha sami? Wasesithi: Ngikutholile, ngoba uzithengisile ukwenza okubi emehlweni eNkosi.
Ahabu sì wí fún Elijah pé, “Ìwọ ti rí mi, ìwọ ọ̀tá mi!” Ó sì dáhùn wí pé, “Èmi ti rí ọ, nítorí tí ìwọ ti tan ara rẹ láti ṣe búburú níwájú Olúwa.
21 Khangela, ngizakwehlisela ububi, ngiqothule inzalo yakho, ngiqume asuke kuAhabi ochamela emdulini, lovalelweyo lokhululekileyo koIsrayeli.
‘Èmi yóò mú ibi wá sórí rẹ. Èmi yóò sì mú ìran rẹ kúrò, èmi yóò sì ké kúrò lọ́dọ̀ Ahabu gbogbo ọmọdé ọkùnrin, àti ọmọ ọ̀dọ̀, àti òmìnira ní Israẹli.
22 Njalo ngizakwenza indlu yakho ibe njengendlu kaJerobhowamu indodana kaNebati lanjengendlu kaBahasha indodana kaAhiya, ngenxa yesicunulo ongicunule ngaso, wenza uIsrayeli one.
Èmi yóò ṣe ilé rẹ bí ilé Jeroboamu, ọmọ Nebati, àti bí ilé Baaṣa, ọmọ Ahijah, nítorí ìwọ ti mú mi bínú, ìwọ sì ti mú Israẹli ṣẹ̀.’
23 LangoJezebeli laye iNkosi yakhuluma isithi: Izinja zizamudla uJezebeli emthangaleni weJizereyeli.
“Àti ní ti Jesebeli pẹ̀lú Olúwa wí pé, ‘Àwọn ajá yóò jẹ Jesebeli nínú yàrá Jesreeli.’
24 OkaAhabi ofela phakathi komuzi zizamudla izinja, lofela egangeni zizamudla inyoni zamazulu.
“Àwọn ajá yóò jẹ ẹni Ahabu tí ó kú ní ìlú, àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run yóò jẹ àwọn ẹni tí ó kú ní igbó.”
25 Kodwa kakubanga khona onjengoAhabi owazithengisa ukwenza okubi emehlweni eNkosi, uJezebeli umkakhe amkhuthazayo.
(Kò sí ẹnìkan bí Ahabu tí ó ta ara rẹ̀ láti ṣe búburú níwájú Olúwa, ẹni tí Jesebeli aya rẹ̀ ń tì.
26 Wenza amanyala kakhulu ngokulandela izithombe, njengakho konke amaAmori akwenzayo, iNkosi eyawaxotsha elifeni phambi kwabantwana bakoIsrayeli.
Ó sì ṣe ohun ìríra gidigidi ní tí tọ òrìṣà lẹ́yìn, gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí àwọn ará Amori ti ṣe, tí Olúwa lé jáde níwájú àwọn ọmọ Israẹli.)
27 Kwasekusithi uAhabi esizwa lamazwi wadabula izigqoko zakhe, wafaka isaka phezu komzimba wakhe, wazila ukudla, walala ngesaka, wahamba buthakathaka.
Nígbà tí Ahabu sì gbọ́ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya, ó sì fi aṣọ ọ̀fọ̀ sí ara rẹ̀, ó sì gbààwẹ̀. Ó sì dùbúlẹ̀ nínú aṣọ ọ̀fọ̀, ó sì ń lọ jẹ́ẹ́.
28 Ilizwi leNkosi laselifika kuElija umTishibi lisithi:
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Elijah ará Tiṣibi wá wí pé,
29 Ubonile yini ukuthi uAhabi uzithobe phambi kwami? Ngenxa yokuthi ezithobile phambi kwami kangiyikuletha ububi ensukwini zakhe; ensukwini zendodana yakhe ngizaletha lobububi endlini yakhe.
“Ǹjẹ́ ìwọ ti rí bí Ahabu ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀ níwájú mi? Nítorí tí ó ti rẹ̀ ara rẹ̀ sílẹ̀, èmi kì yóò mú ibi náà wá ní ọjọ́ rẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò mú u wá sí ilé rẹ̀ ní ọjọ́ ọmọ rẹ̀.”

< 1 Amakhosi 21 >