< UHoseya 13 >

1 Lapho u-Efrayimi ekhuluma, abantu bathuthumela; wabatshazwa ko-Israyeli. Kodwa waba lecala lokukhonza uBhali wasesifa.
Nígbà ti Efraimu bá ń sọ̀rọ̀, àwọn ènìyàn máa ń wárìrì, a gbé e ga ní Israẹli ṣùgbọ́n ó jẹ̀bi ẹ̀sùn pé ó ń sin òrìṣà Baali, ó sì kú.
2 Khathesi benza izono njalonjalo; bazenzela izithombe ngesiliva sabo, izifanekiso ezenziwe ngokuhlakanipha, zonke ziyimisebenzi yezingcitshi. Ngabantu laba kuthiwa, “Banikela imihlatshelo yabantu, bange izithombe zamathole.”
Báyìí, wọ́n ń dá ẹ̀ṣẹ̀ kún ẹ̀ṣẹ̀; wọn fi fàdákà ṣe ère òrìṣà fúnra wọn; ère tí a fi ọgbọ́n dá àrà sí, gbogbo wọn jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ oníṣọ̀nà. Wọn ń sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Pé, “Jẹ́ kí àwọn ènìyàn tí ń rú ẹbọ fi ẹnu, ko àwọn ẹgbọrọ màlúù ni ẹnu.”
3 Ngakho bazakuba njengenkungu yekuseni, njengamazolo ekuseni anyamalalayo, njengamakhoba asuka ezizeni, njengentuthu iphuma ewindini.
Nítorí náà wọn yóò dàbí ìkùùkuu òwúrọ̀, bí ìrì òwúrọ̀ kùtùkùtù tó máa ń parẹ́, bí i èèpo ìyẹ̀fun tí afẹ́fẹ́ gbé láti ibi ìpakà bí èéfín tó rú jáde gba ojú fèrèsé.
4 “Kodwa mina nginguThixo uNkulunkulu wenu, owalikhupha elizweni laseGibhithe. Kaliyikwamukela omunye uNkulunkulu ngaphandle kwami, hatshi omunye uMsindisi ngaphandle kwami.
“Ṣùgbọ́n Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ̀, ẹni tó mú ọ jáde láti ilẹ̀ Ejibiti wá. Ìwọ̀ kì yóò sì mọ ọlọ́run mìíràn àfi èmi kò sí olùgbàlà mìíràn lẹ́yìn mi.
5 Ngalilondoloza enkangala, elizweni elilokutshisa okuvuthayo.
Mo ṣe ìtọ́jú rẹ ní aginjù, ní ilẹ̀ tí ó gbẹ tí kò ní omi.
6 Lapho ngibapha ukudla, basutha; sebesuthi, basuka bazigqaja; basebengikhohlwa.
Wọn ni ìtẹ́lọ́rùn nígbà tí mo fún wọn ní oúnjẹ, Nígbà tí wọ́n ní ìtẹ́lọ́rùn tan wọ́n di agbéraga. Nígbà náà ni wọ́n sì gbàgbé mi.
7 Ngizakwehlela phezu kwabo njengesilwane, ngizacathama ngasendleleni njengengwe.
Nítorí náà, Èmi yóò dìde sí wọn bí i kìnnìún, Èmi yóò fi ara pamọ́ dè wọ́n lọ́nà bí i ẹkùn.
8 Njengebhele elithathelwe imidlwane yalo ngizabahlasela ngibaqhaqhe. Ngizabadla njengesilwane, inyamazana yeganga izabadabula.
Beari igbó tí a já ọmọ rẹ̀ gbà, Èmi yóò bá wọn jà bí? Èmi yóò sì fà wọ́n ya bí ìgbà tí ẹkùn bá fa ara wọn ya bi ẹranko búburú ni èmi yóò fa wọn ya.
9 Uchithiwe, wena Israyeli, ngoba umelane lami, umelane lomsizi wakho.
“A ti pa ọ́ run, ìwọ Israẹli, nítorí pé ìwọ lòdì sí mi, ìwọ lòdì sí olùrànlọ́wọ́ rẹ.
10 Ingaphi inkosi yakho, ukuba ikusize na? Bangaphi ababusi bakho kuwo wonke amadolobho akho, bona owathi ngabo, ‘Ngipha inkosi lababusi’?
Níbo ni ọba rẹ gbé wà nísinsin yìí kí ó bá à le gbà ọ là? Níbo ni àwọn olórí ìlú yín wà, àwọn tí ẹ sọ pé, ‘Fún wa ní ọba àti ọmọ-aládé’?
11 Ngakho ngakunika inkosi ngithukuthele, njalo ngolaka lwami ngayisusa.
Nítorí èyí nínú ìbínú mi ni mo fún un yín ní ọba, nínú ìbínú gbígbóná mi, mo sì mú un kúrò.
12 Icala lika-Efrayimi ligciniwe, izono zakhe zigcinwe emibhalweni.
Ẹ̀bi Efraimu ni a tí ko jọ gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ wà nínú àkọsílẹ̀.
13 Ufikelwa yibuhlungu obunjengowesifazane ehelelwa, kodwa ungumntwana ongelalwazi; lapho isikhathi sifika, kabuyi ekuvulekeni kwesizalo.
Ìrora bí obìnrin tó fẹ́ bímọ ti dé bá a, ṣùgbọ́n ó jẹ́ ọmọ tí kò lọ́gbọ́n, nígbà tí àsìkò tó, ó kọ̀ láti jáde síta láti inú.
14 Ngizabahlenga emandleni engcwaba; ngizabasindisa ekufeni. Zingaphi, we kufa izifo zakho? Kungaphi, we ngcwaba, ukuchitha kwakho? Kangiyikuba lesihawu, (Sheol h7585)
“Èmi yóò rà wọ́n padà kúrò lọ́wọ́ agbára isà òkú. Èmi yóò rà wọ́n padà lọ́wọ́ ikú, ikú, àjàkálẹ̀-ààrùn rẹ dà? Isà òkú, ìparun rẹ dà? “Èmi kò ní ṣàánú mọ́. (Sheol h7585)
15 lanxa ekhula phakathi kwabafowabo. Umoya wasempumalanga ovela kuThixo uzafika, uphephetha uvela enkangala; intwasa yakhe izakwehluleka, lemithombo yakhe itshe. Indlu yakhe yokugcinela izaphangwa yonke ingcebo yayo.
Bí ó tilẹ̀ gbilẹ̀ láàrín àwọn arákùnrin rẹ̀ afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn láti ọ̀dọ̀ Olúwa yóò wá, yóò fẹ́ wá láti inú aginjù orísun omi rẹ̀ yóò gbẹ kànga rẹ̀ yóò gbẹ pẹ̀lú olè yóò fọ́ ilé ẹrù àti gbogbo ilé ìṣúra rẹ̀.
16 Abantu baseSamariya kuzamela balithwale icala labo, ngoba bamhlamukele uNkulunkulu wabo. Bazabulawa ngenkemba; insane zabo zizasakazelwa phansi, abesifazane babo abazithweleyo baqhaqhwe.”
Ará Samaria gbọdọ̀ ru ẹ̀bi wọn, nítorí pé wọ́n ti ṣọ̀tẹ̀ sí Ọlọ́run wọn. Wọn ó ti ipa idà ṣubú; a ó fọ́ àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀, a ó sì la àwọn aboyún wọn nínú.”

< UHoseya 13 >