< Hakaraia 5 >

1 Na ka maranga ake ano oku kanohi, a ka kite, na ko tetahi pukapuka e rere a manu ana.
Nígbà náà ni mo yípadà, mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, ìwé kíká ti ń fò.
2 Na ka mea ia ki ahau, Ko te aha tau e kite na? Ano ra ko ahau, He pukapuka e rere ana taku e kite nei; ko tona roa e rua tekau whatianga, ko tona whanui kotahi tekau whatianga.
Ó sì wí fún mi pé, “Kí ni ìwọ rí?” Èmi sì dáhùn pé, “Mo rí ìwé kíká tí ń fò; gígùn rẹ̀ jẹ́ ogún ìgbọ̀nwọ́, ìbú rẹ̀ sì jẹ́ ìgbọ̀nwọ́ mẹ́wàá.”
3 Katahi ia ka mea mai ki ahau, Ko te kanga tenei ka puta atu nei ki te mata o te whenua katoa: ko nga tangata katoa hoki e tahae ana ka hatepea atu i tetahi taha, ka rite ki ta tenei; a ko nga tangata katoa e oati teka ana, ka hatepea atu i tera t aha, ka rite ki ta tenei.
Ó sì wí fún mi pé, “Èyí ni ègún tí ó jáde lọ sí gbogbo ilẹ̀ ayé, nítorí gbogbo àwọn tí ó bá jalè ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀; gbogbo àwọn tí ó bá sì búra èké ni a ó ké kúrò láti ìhín lọ nípa rẹ̀.
4 Maku ano e mea kia puta atu, e ai ta Ihowa o nga mano, a ka uru ki te whare o te tahae, ki te whare hoki o te tangata i oatitia tekatia ai toku ingoa; a ka noho ki roto ki tona whare, a pau noa ona rakau me ona kohatu.
Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Èmi yóò mú un jáde, Èmi yóò si wọ inú ilé olè lọ, àti inú ilé ẹni ti o bá fi orúkọ mi búra èké, yóò si wà ni àárín ilé rẹ̀, yóò si rún pẹ̀lú igi àti òkúta inú rẹ̀.’”
5 Katahi te anahera i korero ra ki ahau ka puta, a ka mea ki ahau, Tena ra, e ara ou kanohi, tirohia ko te aha tenei ka puta nei.
Angẹli tí ń bá mi sọ̀rọ̀ sì jáde lọ, ó sì wí fún mi pé, “Gbé ojú rẹ sókè nísinsin yìí, kí o sì wo nǹkan tí yóò jáde lọ.”
6 Ano ra ko ahau, He aha koia? A ka ki mai ia, Ko te epa tenei e puta nei. I ki mai ano ia, Ko to ratou ahua tenei i te whenua katoa:
Mo sì wí pé, “Kí ni nǹkan náà?” Ó sì wí pé, “Èyí ni òsùwọ̀n tí ó jáde lọ.” Ó sì wí pé, “Èyí ni àwòrán ní gbogbo ilẹ̀ ayé.”
7 Na ko tetahi taranata mata kua oti te hapai ake: a he wahine tenei e noho nei i roto i te epa.
Sì kíyèsi i, a gbé tálẹ́ǹtì òjé sókè, obìnrin kan sì nìyìí tí ó jókòó sí àárín àpẹẹrẹ òsùwọ̀n.
8 Na ka ki ia, Ko te Kino tenei; na maka iho ana ia e ia ki roto ki te epa: a maka ana e ia te poro mata ki runga ki te ngutu o taua epa.
Ó sì wí pé, “Èyí ni ìwà búburú.” Ó sì ti sí àárín òsùwọ̀n, ó sì ju ìdérí òjé sí ẹnu rẹ̀.
9 Katahi ka maranga ake oku kanohi, ka kite, na ko nga wahine tokorua e puta mai ana, i roto hoki te hau i o raua parirau; ko o raua parirau hoki koia ano kei o te taka; a hapainga ake ana e raua te epa ki te takiwa o te whenua, o te rangi.
Mo sì gbé ojú mi sókè, mo sì wò, sì kíyèsi i, obìnrin méjì jáde wá, ẹ̀fúùfù sì wá nínú ìyẹ́ wọn; nítorí wọ́n ní ìyẹ́ bí ìyẹ́ àkọ̀, wọ́n sì gbé àpẹẹrẹ òsùwọ̀n náà dé àárín méjì ayé àti ọ̀run.
10 Katahi ahau ka mea atu ki te anahera i korero ra ki ahau, E maua ana e enei te epa ki hea?
Mo sì sọ fún angẹli tí ó ń bá mi sọ̀rọ̀ pé, “Níbo ni àwọn wọ̀nyí ń gbé òsùwọ̀n náà lọ.”
11 A ka ki mai tera ki ahau, Hei hanga whare mona ki te whenua o Hinara: a ka pumau ki reira, ka whakaturia ki tona turanga.
Ó si wí fún mi pé, “Sí orílẹ̀-èdè Babeli láti kọ ilé fún un. Tí ó bá ṣetán, a ó sì fi ìdí rẹ̀ mulẹ̀, a o sì fi ka orí ìpìlẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.”

< Hakaraia 5 >