< Hakaraia 13 >

1 I taua ra ka tuwhera he puna mo te whare o Rawiri, mo nga tangata ano o Hiruharama, hei mea mo te hara, mo te poke.
“Ní ọjọ́ náà ìsun kan yóò ṣí sílẹ̀ fún ilé Dafidi àti fún àwọn ará Jerusalẹmu, láti wẹ̀ wọ́n mọ́ kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ àti àìmọ́ wọn.
2 I taua ra, e ai ta Ihowa o nga mano, ka hatepea atu e ahau nga ingoa o nga whakapakoko i runga i te whenua; e kore ano e maharatia a muri ake nei; ka kore ano i ahau nga poropiti, me te wairua poke, i runga i te whenua.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, ni èmi ó gé orúkọ àwọn òrìṣà kúrò ni ilẹ̀ náà, a kì yóò sì rántí wọn mọ́, àti pẹ̀lú èmi ó mú àwọn wòlíì èké àti àwọn ẹ̀mí àìmọ́ kúrò ni ilẹ̀ náà.
3 Na, tenei ake, ki te poropiti tetahi a muri ake nei, ka mea tona papa ki a ia, raua ko tona whaea i whanau ai ia, E kore koe e ora; kua korero teka hoki koe i runga i te ingoa o Ihowa: na ka werohia ia e tona papa raua ko tona whaea i whanau ai i a, ina poropiti ia.
Yóò sì ṣe, nígbà tí ẹnìkan yóò sọtẹ́lẹ̀ síbẹ̀, ni baba rẹ̀ àti ìyá rẹ̀ tí ó bí í yóò wí fún un pé, ‘Ìwọ ki yóò yè, nítorí ìwọ ń sọ ọ̀rọ̀ èké ni orúkọ Olúwa.’ Àti baba rẹ̀ àti ìyá rẹ̀ tí o bí í yóò gun un ni àgúnpa nígbà tí ó bá sọtẹ́lẹ̀.
4 I taua ra ka whakama nga poropiti, tenei, tenei, ki tana kite, i te mea ka poropiti ia; e kore ano e kakahuria e ratou he kakahu huruhuru hei mea tinihanga.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, ojú yóò tí àwọn wòlíì èké olúkúlùkù nítorí ìran rẹ̀, nígbà tí òun ba tí sọtẹ́lẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni wọn kì yóò sì wọ aṣọ wòlíì onírun rẹ̀ tí o fi ń tan ní jẹ.
5 Engari ka mea ia, Ehara ahau i te poropiti, he paruauru ahau, he pononga hoki ahau no toku taitamarikitanga ake.
Ṣùgbọ́n òun o wí pé, ‘Èmi kí í ṣe wòlíì, àgbẹ̀ ni èmi; nítorí tí a ti fi mí ṣe ìránṣẹ́ láti ìgbà èwe mi wá.’
6 A ka mea tetahi ki a ia, He aha enei patunga i ou ringa? a ka mea ia, Ko oku patunga i roto i te whare o oku hoa aroha.
Ẹnìkan ó sì wí fún un pé, ‘Ọgbẹ́ kín ní wọ̀nyí ni ẹ̀yìn rẹ?’ Òun o sì dáhùn pé, ‘Wọ̀nyí ni ibi tí a ti sá mi ní ilé àwọn ọ̀rẹ́ mi.’
7 E ara, e te hoari, ki taku hepara, ki te tangata i takahoatia ki ahau, e ai ta Ihowa o nga mano; patua te hepara, kia marara hoki nga hipi; ka tahuri atu ano toku ringa ki nga mea ririki.
“Dìde, ìwọ idà, sí Olùṣọ́-àgùntàn mi, àti sí ẹni tí í ṣe ẹnìkejì mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Kọlu Olùṣọ́-àgùntàn, àwọn àgùntàn a sì túká: èmi o sì yí ọwọ́ mi sí àwọn kéékèèké.
8 Na i te whenua katoa, e ai ta Ihowa, e rua nga wahi o reira ka hatepea atu, ka mate; ka toe ia te tuatoru o nga wahi ki reira.
Yóò sì ṣe, ni gbogbo ilẹ̀,” ni Olúwa wí, “a ó gé apá méjì nínú rẹ̀ kúrò yóò sì kú; ṣùgbọ́n apá kẹta yóò kù nínú rẹ̀.
9 Ka kawea ano e ahau te tuatoru o nga wahi i roto i te ahi, ka tahia hoki te para, ka peratia me te hiriwa e tahia ana, ka whakamatautauria ano ratou e ahau, ka peratia me te koura; ka karanga ratou ki toku ingoa, a ka whakarongo ahau ki a ratou: ka mea ahau, He iwi ratou naku; a ka mea ratou, Ko Ihowa toku Atua.
Èmi ó sì mú apá kẹta náà la àárín iná, èmi yóò sì yọ́ wọn bí a ti yọ́ fàdákà, èmi yóò sì dán wọn wò, bi a tí ń dán wúrà wò: wọn yóò sì pé orúkọ mi, èmi yóò sì dá wọn lóhùn: èmi yóò wí pé, ‘Àwọn ènìyàn mi ni,’ àwọn yóò sì wí pé, ‘Olúwa ni Ọlọ́run wa.’”

< Hakaraia 13 >