< Hakaraia 10 >

1 Inoia he ua i a Ihowa i te wa o to muri ua; ara i a Ihowa e hanga nei i nga uira, he nui ano te ua e homai e ia ki a ratou, he tarutaru i te mara ma tenei, ma tenei.
Ẹ béèrè òjò nígbà àrọ̀kúrò ni ọwọ́ Olúwa; Olúwa tí o dá mọ̀nàmọ́ná, tí ó sì fi ọ̀pọ̀ òjò fún ènìyàn, fún olúkúlùkù koríko ní pápá.
2 He tekateka noa hoki te korero a nga terapimi, he teka te kite a nga tohunga, he horihori nga moe i korerotia e ratou; he hanga noa iho ta ratou whakamarie, na reira haere ana ratou ano he kahui hipi; karangirangi kau ana i te kore hepara.
Nítorí àwọn òrìṣà tí sọ̀rọ̀ asán, àwọn aláfọ̀ṣẹ sì tí rí èké, wọn sì tí rọ àlá èké; wọ́n ń tu ni nínú lásán, nítorí náà àwọn ènìyàn náà ṣáko lọ bí àgùntàn, a ṣẹ wọn níṣẹ̀ẹ́, nítorí Olùṣọ́-àgùntàn kò sí.
3 I mura toku riri ki nga hepara, i whiua ano e ahau nga koati toa: kua tae mai hoki a Ihowa o nga mano ki tana kahui, ki te whare o Hura, kua mea i a ratou hei hoiho atanga mona i te tatauranga.
“Ìbínú mi ru sí àwọn darandaran, èmi o sì jẹ àwọn olórí ní yà nítorí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti bẹ agbo rẹ̀, ilé Juda wò, yóò sì fi wọn ṣe ẹṣin rẹ̀ dáradára ní ogun.
4 No roto i a ia te putanga ake o te kohatu o te kokonga, no roto i a ia te whao, no roto i a ia te kopere mo te tatauranga, no roto i a ia nga kaiakiaki katoa, rupeke, rupeke.
Láti ọ̀dọ̀ rẹ̀ ni òkúta igun ilé ti jáde wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni èèkàn àgọ́ tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni ọrún ogun tí wá, láti ọ̀dọ̀ rẹ ni àwọn akóniṣiṣẹ́ gbogbo tí wá.
5 A ka rite ratou ki nga marohirohi e takatakahi ana i o ratou hoariri ki te paru o nga waharoa i te mea e whawhai ana: ka whawhai ano ratou, no te mea kei a ratou a Ihowa, a ka whakama nga kaieke hoiho.
Gbogbo wọn yóò sì dàbí ọkùnrin alágbára ni ogun tí ń tẹ àwọn ọ̀tá wọn mọ́lẹ̀ ní ìgboro, wọn ó sì jagun, nítorí Olúwa wà pẹ̀lú wọn, wọn ó sì dààmú àwọn tí ń gun ẹṣin.
6 Na ka kaha i ahau te whare o Hura, ka ora ano i ahau te whare o Hohepa, ka whakahokia ki te nohoanga; no te mea ka tohungia ratou e ahau, a me te mea kihai ratou i peia e ahau; ko ahau hoki, ko Ihowa, to ratou Atua, ka whakarongo ano ahau ki a ra tou.
“Èmi o sì mú ilé Juda ní agbára, èmi o sì gba ilé Josẹfu là, èmi ó sì tún mú wọn padà nítorí mo tí ṣàánú fún wọn, ó sì dàbí ẹni pé èmi kò ì tì í ta wọ́n nù; nítorí èmi ni Olúwa Ọlọ́run wọn, èmi o sì gbọ́ tiwọn
7 Na ka rite nga Eparaimi ki te marohirohi, ka koa ano to ratou ngakau me te mea na te waina: ka kite ano a ratou tamariki, a ka koa; ka whakamanamana to ratou ngakau ki a Ihowa.
Efraimu yóò sì ṣe bí alágbára, ọkàn wọn yóò sì yọ̀ bi ẹni pé nípa ọtí wáìnì: àní àwọn ọmọ wọn yóò rí í, wọn o sì yọ̀, inú wọn ó sì dùn nínú Olúwa.
8 Ka hi ahau ki a ratou, ka huihui i a ratou; kua hokona hoki ratou e ahau; a ka tini ratou, ka pera me ratou i tini ra.
Èmi ó kọ sí wọn, èmi ó sì ṣà wọ́n jọ; nítorí èmi tí rà wọ́n padà; wọn ó sì pọ̀ sí i gẹ́gẹ́ bí wọ́n tí ń pọ̀ sí í rí.
9 A ka whakatokia ratou e ahau ki roto ki nga iwi, ka mahara ano ratou ki ahau i nga whenua tawhiti, ka ora hoki ratou me a ratou tamariki, a ka hoki.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo tú wọn káàkiri orílẹ̀-èdè: síbẹ̀ wọn ó sì rántí mi ni ilẹ̀ jíjìn; wọn ó sì gbé pẹ̀lú àwọn ọmọ wọn, wọn ó sì tún padà.
10 Ka whakahokia mai ano ratou e ahau i te whenua o Ihipa, ka huihuia mai i Ahiria; ka kawea ano ki te whenua o Kireara, ki Repanona, te kitea he wahi mo ratou.
Èmi ó sì tún mú wọn padà kúrò ni ilẹ̀ Ejibiti pẹ̀lú, èmi ó sì ṣà wọn jọ kúrò ni ilẹ̀ Asiria. Èmi ó sì mú wọn wá sí ilẹ̀ Gileadi àti Lebanoni; a kì yóò sì rí ààyè fún wọn bí ó ti yẹ.
11 Na ka tika atu ia i waenga moana, ara i te raruraru, a ka patu i nga ngaru i te moana, ka maroke hoki nga wahi hohonu o te awa, a ka riro iho te whakapehapeha o Ahiria, ka riro ke ano te hepeta o Ihipa.
Wọn yóò sì la Òkun wàhálà já, yóò sì bori rírú omi nínú Òkun, gbogbo ibú odò ni yóò sì gbẹ, a ó sì rẹ ìgbéraga Asiria sílẹ̀, ọ̀pá aládé Ejibiti yóò sí lọ kúrò.
12 Ka whakakahangia ano ratou e ahau i runga i a Ihowa; ka haereere hoki ratou i runga i tona ingoa, e ai ta Ihowa.
Èmi ó sì mú wọn ní agbára nínú Olúwa; wọn ó sì rìn sókè rìn sódò ni orúkọ rẹ̀,” ni Olúwa wí.

< Hakaraia 10 >