< Nehemia 1 >

1 Ko nga kupu a Nehemia tama a Hakaria. Na, i te marama Kihireu, i te rua tekau o nga tau, i ahau i Huhana, i te whare kingi,
Ọ̀rọ̀ Nehemiah ọmọ Hakaliah. Ní oṣù Kisleu ní ogún ọdún (ìjọba Ahaswerusi ọba Persia) nígbà tí mo wà ní ààfin Susa,
2 Ka tae mai a Hanani, tetahi o oku teina, ratou ko etahi tangata o Hura; a ka ui ahau ki a ratou ki nga Hurai i mawhiti, i mahue o nga whakarau, ki Hiruharama hoki.
Hanani, ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin mi wá láti Juda pẹ̀lú àwọn ọkùnrin kan, mo sì béèrè lọ́wọ́ wọn nípa àwọn Júù tí ó ṣẹ́kù tí wọn kò kó ní ìgbèkùn, àti nípa Jerusalẹmu.
3 A ka mea ratou ki ahau, Ko nga oranga i mahue o nga whakarau i reira i taua kawanatanga he nui te he, te whakahaweatia: kua pakaru hoki te taiepa o Hiruharama, a kua wera ona keti i te ahi.
Wọ́n sọ fún mi pé, “Àwọn tí ó kù tí a kó ní ìgbèkùn tí wọ́n sì padà sí agbègbè ìjọba wà nínú wàhálà púpọ̀ àti ẹ̀gàn. Odi Jerusalẹmu ti wó lulẹ̀ a sì ti fi iná sun ẹnu ibodè rẹ̀.”
4 A, no toku rongonga i enei kupu, ka noho ahau, ka tangi, ka pouri hoki a taka noa etahi ra; na nohopuku ana ahau, inoi ana hoki ki te aroaro o te Atua o nga rangi,
Nígbà tí mo gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jókòó mo sì sọkún. Mo ṣọ̀fọ̀, mo gbààwẹ̀, mo sì gbàdúrà fún ọjọ́ díẹ̀ níwájú Ọlọ́run ọ̀run.
5 A ka mea ahau, Aue, e Ihowa, e te Atua o te rangi, ko te Atua nui ia e wehingia ana, e pupuri ana i te kawenata, i te atawhai mo te hunga e aroha ana ki a ia, e pupuri ana i ana whakahau:
Nígbà náà ni mo wí pé: “Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, Ọlọ́run tí ó tóbi tí ó sì ní ẹ̀rù, tí ó ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ pẹ̀lú wọn tí ó fẹ́ ẹ tí wọ́n sì ń pa àṣẹ mọ́.
6 Tena, kia tahuri mai tou taringa, kia titiro mai ano ou kanohi, kia whakarongo mai ai koe ki te inoi a tau pononga, e inoi atu nei ki tou aroaro i te ao, i te po, mo au pononga, mo nga tama a Iharaira, i ahau e whaki nei i nga hara o nga tama a I haraira i hara ai matou ki a koe; ae ra, kua hara ahau me te whare o toku papa.
Jẹ́ kí etí rẹ kí ó ṣí sílẹ̀, kí ojú ù rẹ kí ó sì ṣí sílẹ̀ láti gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà ní iwájú rẹ ní ọ̀sán àti ní òru fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli. Mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àwa ọmọ Israẹli àti tèmi àti ti ilé baba mi, tí a ti ṣẹ̀ sí ọ.
7 He rawa ta matou mahi ki a koe, kihai hoki i pupuri i nga whakahau, i nga tikanga, i nga whakaritenga i whakahaua e koe ki tau pononga ki a Mohi.
Àwa ti ṣe búburú sí ọ. A kò sì pa àṣẹ ìlànà àti òfin tí ìwọ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ mọ́.
8 Tena, maharatia te kupu i whakahaua e koe ki tau pononga, ki a Mohi, i mea ra koe, Ki te poka ke ta koutou, ka whakamararatia atu koutou e ahau ki roto ki nga iwi;
“Rántí ìlànà tí o fún Mose ìránṣẹ́ rẹ, wí pé, ‘Bí ìwọ bá jẹ́ aláìṣòótọ́, èmi yóò fọ́n yín ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
9 Otiia ki te tahuri mai ano koutou ki ahau, a ka pupuri, ka mahi i aku whakahau, ahakoa i peia etahi o koutou ki te pito whakamutunga o te rangi, ka kohikohia mai ratou e ahau i reira, ka kawea mai ano ki te wahi i whiriwhiria e ahau kia noho toku ingoa ki reira.
Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá yípadà sí mi, tí ẹ bá sì pa àṣẹ mi mọ́, nígbà náà bí àwọn ènìyàn yín tí a kó ní ìgbèkùn tilẹ̀ wà ní jìnnà réré ìpẹ̀kun ọ̀run, èmi yóò kó wọn jọ láti ibẹ̀, èmi yóò sì mú wọn wá, sí ibi tí èmi ti yàn bí i ibùgbé fún orúkọ mi.’
10 Na ko au pononga enei, ko tau iwi i hokona e koe, ara e tou kaha nui, e tou ringa kaha.
“Àwọn ni ìránṣẹ́ rẹ àti ènìyàn rẹ àwọn tí ìwọ rà padà pẹ̀lú agbára ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára ńlá rẹ.
11 Tena, e te Ariki, tahuri mai tou taringa ki te inoi a tau pononga, ki te inoi hoki a au pononga e mea nei kia wehi i tou ingoa: kia tika ra ta tau pononga aianei, homai hoki ki a ia kia atawhaitia e tenei tangata. Ko ahau hoki te kaiwhakainu a t e kingi.
Olúwa, jẹ́ kí etí rẹ ṣí sílẹ̀ sí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ yìí, àti sí àdúrà àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí wọ́n ní inú dídùn láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ. Fún ìránṣẹ́ rẹ ní àṣeyọrí lónìí kí o sì síjú àánú wò ó níwájú ọkùnrin yìí.” Nítorí tí mo jẹ́ agbọ́tí ọba nígbà náà.

< Nehemia 1 >