< Mika 5 >

1 Na inaianei ka whakahuihui a ropu koe i a koe, e te tamahine a nga ropu: kua oti tatou te whakapae e ia: ka patua e ratou ki te rakau te paparinga o te kaiwhakawa o Iharaira.
Nísinsin yìí, kó àwọn ọ̀wọ́ ogun rẹ jọ, ìwọ ìlú ti o ni ọmọ-ogun, nítorí ó ti fi gbógun dó tì wá. Wọn yóò fi ọ̀pá lu àwọn alákòóso Israẹli ní ẹ̀rẹ̀kẹ́.
2 Na ko koe, e Peterehema Eparata, he iti nei i roto i nga mano o Hura, e puta mai i roto i a koe tetahi maku hei kawana mo Iharaira: ko ona putanga nonamata, no nga ra o tua iho.
“Ṣùgbọ́n ìwọ, Bẹtilẹhẹmu Efrata, bí ìwọ ti jẹ́ kékeré láàrín àwọn ẹ̀yà Juda, nínú rẹ ni ẹni tí yóò jẹ́ olórí ní Israẹli yóò ti jáde tọ̀ mí wá, ìjáde lọ rẹ̀ sì jẹ́ láti ìgbà àtijọ́, láti ìgbà láéláé.”
3 Mo reira ratou ka tukua atu ai e ia, kia tae ra ano ki te wa e whanau ai tenei e whakamamae nei: hei reira nga toenga o ona tuakana hoki ai ki nga tama a Iharaira.
Nítorí náà Israẹli yóò di kíkọ̀sílẹ̀ pátápátá títí di àkókò tí ẹni tí ń rọbí yóò fi bí, àti àwọn ìyókù arákùnrin rẹ̀ yóò fi padà láti darapọ̀ mọ́ àwọn Israẹli.
4 A ka tu ia, ka whangai i tana kahui i runga i te kaha o Ihowa, i runga hoki i te nui o te ingoa o Ihowa, o tona Atua; a ka noho ratou; no te mea akuareiia ka nui, ki nga pito ra ano o te whenua.
Òun yóò sì dúró, yóò sì máa ṣe olùṣọ́-àgùntàn àwọn agbo ẹran rẹ̀ ní agbára Olúwa, ní ọláńlá orúkọ Olúwa Ọlọ́run rẹ̀. Wọn yóò sì wà láìléwu, nítorí nísinsin yìí ni títóbi rẹ yóò sì dé òpin ayé.
5 A ko tenei tangata hei maunga rongo mo tatou: ina tae mai te Ahiriana ki to tatou whenua, a ka takahi ki o tatou whare kingi, hei reira ara ai i a tatou hei whawhai ki a ia etahi hepara tokowhitu me etahi tangata rangatira tokowaru.
Òun yóò sì jẹ́ àlàáfíà wọn. Nígbà tí àwọn Asiria bá gbógun sí ilẹ̀ wa tí wọ́n sì ń yan lórí odi alágbára wa, nígbà náà ni a ó gbé olùṣọ́-àgùntàn méje dìde sí i, àti olórí ènìyàn mẹ́jọ.
6 A ka whakamotitia e ratou te whenua o Ahiria ki te hoari, te whenua hoki o Nimiroro i ona tomokanga: na ka whakaorangia tatou e ia i te Ahiriana, ina haere mai ia ki to tatou whenua, ina takahi ia i roto i o tatou rohe.
Wọn yóò sì fi idà pa ilẹ̀ Asiria run, àti ilẹ̀ Nimrodu pẹ̀lú idà tí a fà. Òun yóò sì gbà wá sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn ará Asiria nígbà tí wọn bá gbógun ti ilẹ̀ wa tí wọ́n sì tún yan wọ ẹnu-bodè wa.
7 A ka rite nga toenga o Hakopa i roto i nga iwi maha ki te tomairangi a Ihowa, ki nga kouaua i runga i te tarutaru; e kore nei e whanga ki te tangata, e kore ano e tatari ki nga tama a te tangata.
Ìyókù Jakọbu yóò sì wà láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ènìyàn bí ìrì láti ọ̀dọ̀ Olúwa wa, bí ọ̀wààrà òjò lórí koríko, tí kò gbẹ́kẹ̀lé ènìyàn tàbí kò dúró de àwọn ọmọ ènìyàn.
8 Na ka waiho te toenga o Hakopa i roto i nga tauiwi, i roto i nga iwi maha; ka rite ki te raiona i roto i nga kararehe o te ngahere, ki te kuao raiona i roto i nga kauhui hipi: na ki te tika atu ia i waenga, ka takatakahia e ia, ka haehaea, kahore hoki he kaiwhakaora.
Ìyókù Jakọbu yóò sì wà láàrín àwọn aláìkọlà ní àárín àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn, bí i kìnnìún láàrín àwọn ẹranko inú igbó, bí i ọmọ kìnnìún láàrín agbo àgùntàn, èyí tí ó máa ń fà á ya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, tí ó sì máa ń tẹ̀ ẹ́ mọ́lẹ̀, tí kò sì ṣí ẹnìkan tí ó lè gbà á là.
9 Whakaarahia tou ringa ki runga ake i ou hoariri, hatepea atu hoki ou hoariri katoa.
A ó gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè ní ìṣẹ́gun lórí àwọn ọ̀tá rẹ̀, gbogbo àwọn ọ̀tá rẹ̀ sì ni a ó parun.
10 Na i taua ra, e ai ta Ihowa, ka hatepea atu e ahau au hoiho i roto i a koe, ka kore ano i ahau au hariata;
“Ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí, “Èmi yóò pa àwọn ẹṣin rẹ̀ run kúrò láàrín rẹ èmi yóò sì pa àwọn kẹ̀kẹ́ ogun rẹ̀ run.
11 A ka whakakorea atu e ahau nga pa o tou whenua, ka wawahia ano e ahau ou pa kaha katoa;
Èmi yóò sì pa ilẹ̀ ìlú ńlá rẹ̀ run, èmi ó sì fa gbogbo ibi gíga rẹ̀ ya.
12 Ka hatepea atu hoki e ahau nga makutu i roto i tou ringa, a ka kore nga tohunga maori i roto i a koe:
Èmi yóò gé ìwà àjẹ́ kúrò lọ́wọ́ rẹ̀, ìwọ kì yóò sì ní aláfọ̀ṣẹ mọ́.
13 Ka hatepea atu hoki e ahau au whakapakoko, me au pou whakaahua i roto i a koe: a e kore koe e koropiko i muri nei ki te mahi a ou ringa.
Èmi yóò pa àwọn ère fínfín rẹ̀ run, àti ọwọ̀n rẹ̀ kúrò láàrín rẹ̀; ìwọ kì yóò sì le è foríbalẹ̀ fún iṣẹ́ ọwọ́ rẹ mọ́.
14 Ka hutia ano e ahau Aherimi i roto i a koe: a ka huna e ahau ou pa.
Èmi yóò fa ère Aṣerah tu kúrò láàrín rẹ̀, èmi yóò sì pa ìlú ńlá rẹ̀ run.
15 Ka rapua hoki e ahau he utu i nga tauiwi i runga i te riri, i te weriweri, kihai nei ratou i whakarongo.
Èmi yóò gbẹ̀san ní ìbínú àti ìrunú lórí àwọn orílẹ̀-èdè tí kò ti tẹríba fún mi.”

< Mika 5 >