< Hohua 17 >

1 A ko te rota tenei i te iwi o Manahi; ko ia hoki te matamua a Hohepa. I a Makiri, i te matamua a Manahi, matua o Kireara, i te mea he tangata hapai pakanga ia, i a ia a Kireara, a Pahana.
Èyí ní ìpín ẹ̀yà Manase tí í ṣe àkọ́bí Josẹfu, fún Makiri, àkọ́bí Manase. Makiri sì ni baba ńlá àwọn ọmọ Gileadi, tí ó ti gba Gileadi àti Baṣani nítorí pé àwọn ọmọ Makiri jẹ́ jagunjagun ńlá.
2 A ko te rota i era atu tama a Manahi, i o ratou hapu; i nga tama a Apietere, i nga tama a Hereke, i nga tama a Ahariere, i nga tama a Hekeme, i nga tama a Hewhere, i nga tama hoki a Hemira: ko nga tama enei a Manahi tama a Hohepa, i o ratou hapu.
Nítorí náà ìpín yìí wà fún ìyókù àwọn ènìyàn Manase: ní agbo ilé Abieseri, Heleki, Asrieli, Ṣekemu, Heferi àti Ṣemida. Ìwọ̀nyí ní àwọn ọmọ ọkùnrin Manase ọmọ Josẹfu ní agbo ilé wọn.
3 Otiia kahore he tama a Teropehara, tama a Hewhere, tama a Kireara, tama a Makiri, tama a Manahi; engari he tamahine: a ko nga ingoa enei o ana tamahine, ko Mahara, ko Noa, ko Hokora, ko Mireka, ko Tirita.
Nísinsin yìí Selofehadi ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri, ọmọ Manase, kò ní ọmọkùnrin, bí kò ṣe àwọn ọmọbìnrin, tí orúkọ wọn jẹ́: Mahila, Noa, Hogla, Milka àti Tirsa.
4 Na ka whakatata ratou ki te aroaro o Ereatara tohunga, ki te aroaro o Hohua tama a Nunu, ki te aroaro ano hoki o nga ariki, a ka mea, I whakahau a Ihowa i a Mohi kia homai he kainga tupu ki a matou i roto i o matou tungane. Na homai ana e ia ki a ratou ta Ihowa i ki ai, he kainga tupu i roto i nga teina o to ratou papa.
Wọ́n sì lọ bá Eleasari àlùfáà, Joṣua ọmọ Nuni, àti àwọn olórí wí pé, “Olúwa pàṣẹ fún Mose láti fún wa ní ìní ní àárín àwọn arákùnrin wa.” Bẹ́ẹ̀ ni Joṣua fún wọn ní ìní pẹ̀lú àwọn arákùnrin baba wọn, gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Olúwa.
5 A tekau nga wahi i taka ki a Manahi, haunga te whenua o Kireara, o Pahana, i tawahi o Horano;
Ìpín ilẹ̀ Manase sì jẹ́ ìsọ̀rí mẹ́wàá ní ẹ̀bá Gileadi àti Baṣani ìlà-oòrùn Jordani,
6 No te mea i whiwhi nga tamahine a Manahi i te wahi tupu i roto i ana tama; a i riro te whenua o Kireara i nga tama a Manahi i mahue.
nítorí tí àwọn ọmọbìnrin ẹ̀yà Manase gba ìní ní àárín àwọn ọmọkùnrin. Ilẹ̀ Gileadi sì jẹ́ ti ìyókù àwọn ọmọ Manase.
7 A ko te rohe ki a Manahi kei a Ahera a tae noa ki Mikimeta, ki tera i te ritenga atu o Hekeme; a i haere tonu te rohe ki matau, ki nga tangata o Enetapua.
Agbègbè Manase sì fẹ̀ láti Aṣeri títí dé Mikmeta ní ìlà-oòrùn Ṣekemu. Ààlà rẹ̀ sì lọ sí ìhà gúúsù títí tó fi dé ibi tí àwọn ènìyàn ń gbé ní Tapua,
8 I a Manahi te whenua o Tapua: ko Tapua ia i te rohe o Manahi, i nga tama a Eparaima tera.
(Manase lo ni ilẹ̀ Tapua, ṣùgbọ́n Tapua fúnra rẹ̀ to wà ni ààlà ilẹ̀ Manase jẹ ti àwọn ará Efraimu.)
9 A i puta atu te rohe ki te awa, ki Kana, whaka te tonga o te awa: ko enei pa no Eparaima i roto i nga pa o Manahi: a ko te rohe o Manahi i te taha tuaraki o te awa, a ko ona putanga kei te moana:
Ààlà rẹ̀ sì sọ̀kalẹ̀ lọ odò Kana, ní ìhà gúúsù odò náà. Àwọn ìlú tí ó jẹ́ ti Efraimu wà ní àárín àwọn ìlú Manase, ṣùgbọ́n ààlà Manase ni ìhà àríwá odò náà, ó sì yọ sí Òkun.
10 I a Eparaima te taha ki te tonga, a i a Manahi te taha ki te raki, a ko te moana te rohe ki a ia; a i tutaki raua ki a Ahera ki te raki, ki a Ihakara hoki ki te rawhiti.
Ìhà gúúsù ilẹ̀ náà jẹ́ ti Efraimu, ṣùgbọ́n ìhà àríwá jẹ́ ti Manase. Ilẹ̀ Manase dé Òkun, Aṣeri sì jẹ́ ààlà rẹ̀ ní àríwá, nígbà tí Isakari jẹ́ ààlà ti ìlà-oòrùn.
11 A i riro i a Manahi i roto i to Ihakara, i to Ahera, a Peteheana me ona pa ririki, a Ipireama me ona pa ririki, nga tangata o Roro, o ona pa ririki, nga tangata o Eneroro, o ona pa ririki, nga tangata o Taanaka, o ona pa ririki, nga tangata ano hoki o Mekiro, o ona pa ririki, ara e toru nga taumata.
Ní àárín Isakari àti Aṣeri, Manase tún ni Beti-Ṣeani, Ibleamu àti àwọn ènìyàn Dori, Endori, Taanaki àti Megido pẹ̀lú àwọn abúlé tí ó yí wọn ká (ẹ̀kẹ́ta nínú orúkọ wọn ní Nafoti).
12 Otiia kihai i taea e nga tama a Manahi te pei nga tangata o aua pa; ko nga Kanaani ia i whakamate kia noho tonu i taua whenua.
Síbẹ̀, àwọn ọmọ Manase kò lè gba àwọn ìlú wọ̀nyí, nítorí àwọn ará Kenaani ti pinnu láti gbé ní ilẹ̀ náà.
13 Na, no ka kaha nga tama a Iharaira, ka meinga e ratou nga Kanaani hei kaimahi, a kahore i peia rawatia atu e ratou.
Ṣùgbọ́n nígbà tí àwọn ará Israẹli di alágbára, wọ́n mú àwọn ọmọ Kenaani sìn, ṣùgbọ́n wọn kò lé wọn jáde pátápátá.
14 Na ka korero nga tama a Hohepa ki a Hohua, ka mea, Na te aha i kotahi tonu ai te rota, i kotahi ai te wahi i homai e koe ki ahau hei kainga tupu, he iwi nui nei hoki ahau, a he manaakitanga hoki ahau na Ihowa a mohoa noa nei?
Àwọn ọmọ Josẹfu sì wí fún Joṣua pé, “Èéṣe tí ìwọ fi fún wa ní ìpín ilẹ̀ kan àti ìdákan ní ìní? Nítorí àwa jẹ́ ọ̀pọ̀ ènìyàn tí Olúwa ti bùkún lọ́pọ̀lọ́pọ̀.”
15 Na ka mea a Hohua ki a ratou, Ki te mea he iwi nui koe, haere ki te ngahere tua ai he wahi mau i reira, i te whenua o nga Perihi ratou ko nga Repaima; ina hoki he kuiti rawa te whenua pukepuke o Eparaima mou.
Joṣua dá wọn lóhùn pé, “Bí ẹ bá pọ̀ bẹ́ẹ̀, tí òkè ìlú Efraimu bá kéré fún yin, ẹ gòkè lọ sí igbó kí ẹ sì ṣán ilẹ̀ òkè fún ara yín ní ibẹ̀ ní ilẹ̀ àwọn ará Peresi àti ará Refaimu.”
16 Na ka mea nga tama a Hohepa, He iti rawa te whenua pukepuke mo matou: a ko nga Kanaani katoa e noho ana i te wahi mania he hariata o ratou, o era e noho ra i Peteheana, i ona pa ririki, o era hoki i te mania i Ietereere.
Àwọn ènìyàn Josẹfu dáhùn pé, “Òkè kò tó fún wa, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo àwọn ará Kenaani tí ó gbé ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti gbogbo àwọn tí ń bẹ ní Beti-Ṣeani àti àwọn ìletò àti àwọn tí ń gbé ní àfonífojì Jesreeli ní kẹ̀kẹ́ ogun onírin.”
17 Na ka korero a Hohua ki te whare o Hohepa, ki a Eparaima raua ko Manahi, ka mea, He iwi nui koe, he nui hoki tou kaha: e kore e kotahi tonu te rota mou:
Ṣùgbọ́n Joṣua sọ fún àwọn ilé Josẹfu: fún Efraimu àti Manase pé, “Lóòtítọ́ ni ẹ pọ̀ lọ́pọ̀lọ́pọ̀, ẹ sì jẹ́ alágbára. Ẹ̀yin kí yóò sì ní ìpín kan ṣoṣo.
18 Engari mou ano te whenua pukepuke; ahakoa hoki he ngahere ia, mau e tua, a mou ona putanga atu; ka peia atu hoki e koe nga Kanaani, he ahakoa to ratou whai hariata rino, me to ratou kaha.
Ṣùgbọ́n ilẹ̀ orí òkè igbó jẹ́ tiyín pẹ̀lú. Ẹ ṣán ilẹ̀ náà, òpin rẹ̀ yóò jẹ́ tiyín pátápátá. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé àwọn ará Kenaani ní kẹ̀kẹ́ ogun irin, tí ó sì jẹ́ pé wọ́n ní agbára, síbẹ̀ ẹ lè lé wọn jáde.”

< Hohua 17 >