< Heremaia 1 >

1 Ko nga kupu a Heremaia tama a Hirikia, ko ia nei tetahi o nga tohunga i Anatoto i te whenua o Pineamine:
Èyí ni ọ̀rọ̀ Jeremiah ọmọ Hilkiah ọ̀kan nínú àwọn àlùfáà ní Anatoti ní agbègbè ilẹ̀ Benjamini.
2 I puta nei ki a ia te kupu a Ihowa i nga ra o Hohia tama a Amono, kingi o Hura, i te tekau ma toru o nga tau o tona kingitanga.
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ ọ́ wá ní ọdún kẹtàlá ní àkókò ìjọba Josiah ọmọ Amoni ọba Juda,
3 I puta ano hoki i nga ra o Iehoiakimi tama a Hohia kingi o Hura, a taka noa te tekau ma tahi o nga tau o Terekia tama a Hohia kingi o Hura, taea noatia te whakaraunga o Hiruharama i te rima o nga marama.
àti títí dé àsìkò Jehoiakimu ọmọ Josiah ọba Juda, títí dé oṣù karùn-ún ọdún kọkànlá Sedekiah ọmọ Josiah ọba Juda, nígbà tí àwọn ará Jerusalẹmu lọ sí ìgbèkùn.
4 Na i puta te kupu a Ihowa ki ahau, i mea,
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ̀ mí wá, wí pé,
5 Kiano koe i hanga e ahau i roto i te kopu, kua mohio ahau ki a koe, a kiano koe i puta mai i te puku, kua whakatapua koe e ahau; kua whakaritea koe e ahau hei poropiti ki nga iwi.
“Kí ó tó di pé mo dá ọ láti inú ni mo ti mọ̀ ọ́n, kí ó sì tó di pé a bí ọ ni mo ti yà ọ́ sọ́tọ̀. Mo yàn ọ́ gẹ́gẹ́ bí wòlíì fún àwọn orílẹ̀-èdè.”
6 Na ka mea ahau, Aue, e Ihowa, e te Atua, nana, kahore e taea e ahau te korero, he tamariki nei hoki ahau.
Mo sọ pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè, ọmọdé ni mí, èmi kò mọ bí a ṣe é sọ̀rọ̀.”
7 Ano ra ko Ihowa ki ahau, Kaua e mea, He tamariki ahau: no te mea, ahakoa ko wai te hunga e unga atu ai koe e ahau, me haere tonu koe, me korero hoki e koe nga mea katoa e whakahaua e ahau ki a koe.
Olúwa sọ fún mi pé, “Má ṣe sọ pé, ‘Ọmọdé lásán ni mí.’ O gbọdọ̀ ní láti lọ sí ọ̀dọ̀ gbogbo àwọn tí mo rán ọ sí, kí o sì sọ ohun tí mo pàṣẹ fún ọ.”
8 Kaua e wehi i a ratou; kei a koe hoki ahau hei whakaora i a koe, e ai ta Ihowa.
Olúwa sì wí pé má ṣe bẹ̀rù wọn, nítorí tí èmi wà pẹ̀lú rẹ èmi ó sì gbà ọ́.
9 Na ka totoro mai te ringa o Ihowa, a ka pa ki toku mangai; a ka mea a Ihowa ki ahau, Nana, kua hoatu nei e ahau aku kupu ki tou mangai:
Olúwa sì na ọwọ́ rẹ̀, ó sì fi kàn mí lẹ́nu, ó sì wí fún mi pé nísinsin yìí, mo ti fi ọ̀rọ̀ mi sí inú ẹnu rẹ.
10 Titiro, no tenei ra i meinga ai koe e ahau hei whakatakoto tikanga ki nga iwi, ki nga kingitanga, hei unu atu, hei wahi iho, hei whakangaro, hei turaki iho, hei hanga, hei whakato.
Wò ó, mo yàn ọ́ lórí àwọn orílẹ̀-èdè àti ìjọba gbogbo láti fàtu, láti wó lulẹ̀, láti bàjẹ́, láti jágbà, láti máa kọ́, àti láti máa gbìn.
11 I puta mai ano te kupu a Ihowa ki ahau, i mea, He aha te mea e kite na koe, e Heremaia? Ano ra ko ahau, He peka aramona taku e kite nei.
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ mí wá wí pé: “Kí ni o rí Jeremiah?” Mo sì dáhùn wí pé, “Mo rí ẹ̀ka igi almondi.”
12 Ano ra ko Ihowa ki ahau, Ka pai tau tirohanga atu; no te mea ka tirohia e ahau taku kupu, ka mahia.
Olúwa sì wí fún mi pé, “Ó ti rí i bí ó ṣe yẹ, nítorí pé mo ti ń ṣọ láti rí i pé ọ̀rọ̀ mi wá sí ìmúṣẹ.”
13 Na ko te rua o nga putanga mai o te kupu a Ihowa ki ahau; i mea ia, He aha te mea e kite na koe? Ano ra ko ahau, He kohua e koropupu ana taku e kite nei, a ko tona mata e anga mai ana i te raki.
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tún tọ̀ mi wá ní ẹ̀ẹ̀kejì pé, “Kí ni o rí?” Mo sì dáhùn pé mo rí ìkòkò gbígbóná, tí ó ń ru láti apá àríwá.
14 Na ka mea a Ihowa ki ahau, Ka puta mai i te raki he kino mo nga tangata katoa o te whenua.
Olúwa sì wí fún mi pé, “Láti apá àríwá ni a ó ti mu ìdààmú wá sórí gbogbo àwọn tí ó ń gbé ní ilẹ̀ náà.
15 Tenei hoki ahau te karanga nei ki nga hapu katoa o nga kingitanga o te raki, e ai ta Ihowa; a ka haere mai ratou, ka whakatu i tona torona, i tona torona, ki te tomokanga i nga kuwaha o Hiruharama, ki ona taiepa katoa, a karapoi noa, ki nga pa k atoa ano o Hura.
Mo sì ti ṣetán láti pe gbogbo àwọn ènìyàn orílẹ̀-èdè àríwá níjà,” ni Olúwa wí. “Àwọn ọba wọn yóò wá gbé ìtẹ́ wọn ró ní ojú ọ̀nà àbáwọlé Jerusalẹmu. Wọn ó sì dìde sí gbogbo àyíká wọn àti sí gbogbo àwọn ìlú Juda.
16 Ka puaki ano i ahau aku whakawakanga ki a ratou mo o ratou kino katoa; mo ratou i whakarere i ahau, i tahu whakakakara ki nga atua ke, i koropiko ki nga mahi a o ratou ringa.
Èmi yóò sì kéde ìdájọ́ mi lórí àwọn ènìyàn mi nítorí ìwà búburú wọn nípa kíkọ̀ mí sílẹ̀, nípa rírúbọ sí ọlọ́run mìíràn àti sínsin àwọn ohun tí wọ́n fi ọwọ́ wọn ṣe.
17 Na, ko koe, whitikiria tou hope, whakatika, korerotia ki a ratou nga mea katoa e whakahaua e ahau ki a koe; aua e wehi i a ratou, kei meinga koe e ahau kia numinumi kau ki to ratou aroaro.
“Wà ní ìmúrasílẹ̀! Dìde dúró kí o sì sọ fún wọn ohunkóhun tí mo bá pàṣẹ fún wọn. Má ṣe jẹ́ kí wọ́n dẹ́rùbà ọ́, èmi yóò sì sọ ọ́ di ẹ̀rù níwájú wọn.
18 No te mea hoki kua meinga koe e ahau i tenei ra hei pa taiepa, hei pou rino, hei taiepa parahi ki te whenua katoa, ki nga kingi o Hura, ki ona rangatira, ki ona tohunga, ki te iwi ano o te whenua.
Ní òní èmi ti sọ ọ́ di ìlú alágbára, òpó irin àti odi idẹ sí àwọn ọba Juda, àwọn ìjòyè rẹ̀, sí àwọn àlùfáà àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà.
19 A ka whawhai ratou ki a koe, otira e kore koe e taea e ratou; no te mea kei a koe ahau, e ai ta Ihowa, hei whakaora i a koe.
Wọn yóò dojú ìjà kọ ọ́, wọn kì yóò borí rẹ, nítorí wí pé èmi wà pẹ̀lú rẹ, èmi yóò sì gbà ọ́,” ni Olúwa wí.

< Heremaia 1 >