< Heremaia 5 >

1 E oma, kopikopiko koutou i nga ara o Hiruharama, tirohia kia mohio ai koutou, rapua i nga waharoa o reira, me kahore e kite i tetahi tangata, mehemea tera he tangata e whakarite pai ana, e rapu ana i te pono; a ka murua e ahau nga he o reira.
“Lọ sókè àti sódò àwọn òpópó Jerusalẹmu, wò yíká, kí o sì mọ̀, kí o sì wá kiri. Bí o bá le è rí ẹnìkan, tí ó jẹ́ olóòtítọ́ àti olódodo, n ó dáríjì ìlú yìí.
2 Na ahakoa mea noa ratou, Kei te ora a Ihowa; he pono he oati teka ta ratou.
Bí wọ́n tilẹ̀ wí pé, ‘Bí Olúwa ti ń bẹ,’ síbẹ̀ wọ́n búra èké.”
3 He teka ianei, e Ihowa, kei runga ou kanohi i te pono? i whiua ratou e koe, heoi kihai i pouri; moti iho ratou i a koe, heoi kahore i pai kia anga mai ki te ako; kua meinga e ratou o ratou mata kia maro atu i te kohatu, kua kore e pai ki te hoki mai.
Olúwa, ojú rẹ kò ha wà lára òtítọ́? Ìwọ lù wọ́n, kò dùn wọ́n; ìwọ bá wọn wí, wọ́n kọ̀ láti yípadà. Wọ́n mú ojú wọn le ju òkúta lọ, wọ́n sì kọ̀ láti yípadà.
4 Koia ahau i mea ai, He pono he rawakore enei, he kuware, kahore hoki ratou e mohio ki te ara a Ihowa, ki te whakarite a to ratou Atua;
Èmi sì rò pé, “Tálákà ni àwọn yìí; wọn jẹ́ aṣiwèrè, nítorí pé wọn kò mọ ọ̀nà Olúwa, àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.
5 Ka haere ahau ki nga tangata rarahi, ka korero ki a ratou; e mohio ana hoki ratou ki te ara a Ihowa, ki te whakarite a to ratou Atua: heoi ko enei, kotahi tonu ratou tahi nana i wawahi te ioka, i motumotu hoki nga here.
Nítorí náà, èmi yóò tọ àwọn adarí lọ, n ó sì bá wọn sọ̀rọ̀; ó dájú wí pé wọ́n mọ ọ̀nà Olúwa àti ohun tí Ọlọ́run wọn ń fẹ́.” Ṣùgbọ́n pẹ̀lú ìfìmọ̀ṣọ̀kan, wọ́n ti ba àjàgà jẹ́, wọ́n sì ti já ìdè.
6 Mo reira ka whakamatea ratou e te raiona i roto i te ngahere, ka pahuatia e te wuruhi o nga ahiahi, ka tuteia o ratou pa e te reparo, ko te hunga katoa e puta mai ki waho ka haehaea; he maha hoki o ratou pokanga ketanga, kua nui haere o ratou tah uritanga ketanga.
Nítorí náà, kìnnìún láti inú igbó yóò kọlù wọ́n, ìkookò aginjù yóò sì pa wọ́n run, ẹkùn yóò máa ṣe ibùba sí ẹ̀bá ìlú yín ẹnikẹ́ni tí ó bá jáde ni yóò fàya pẹ́rẹpẹ̀rẹ, nítorí àìgbọ́ràn yín pọ, ìpadàsẹ́yìn wọn sì pọ̀.
7 Me pehea e murua ai e ahau tenei he ou? kua whakarere nei au tama i ahau, oatitia ana e ratou nga mea ehara nei i te atua; i to ratou makonatanga i taku kai, na kei te puremu, ropu tonu ratou i roto i nga whare o nga wahine kairau.
“Kí ni ṣe tí èmi ó ṣe dáríjì ọ́? Àwọn ọmọ rẹ ti kọ̀ mí sílẹ̀ àti pé wọ́n ti fi ọlọ́run tí kì í ṣe Ọlọ́run búra. Mo pèsè fún gbogbo àìní wọn, síbẹ̀ wọ́n tún ń ṣe panṣágà wọ́n sì kórajọ sí ilé àwọn alágbèrè.
8 Ko to ratou rite kei te hoiho whangai i te ata: e tangi ana ki te wahine a tona hoa, a tona hoa.
Wọ́n jẹ́ akọ ẹṣin tí a bọ́ yó, tí ó lágbára, wọ́n sì ń sọkún sí aya arákùnrin wọn.
9 E kore ianei ahau e whiu mo enei mea? e ai ta Ihowa: e kore ianei toku wairua e rapu utu i te iwi penei?
Èmi kì yóò ha ṣe ìbẹ̀wò nítorí nǹkan wọ̀nyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gba ẹ̀san fúnra mi lára irú orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
10 Haere koutou ki runga ki ona taiepa wawahi ai; otiia kaua e whakapaua rawatia; whakakahoretia ona pekerangi; ehara hoki ena i a Ihowa
“Lọ sí ọgbà àjàrà rẹ̀, kí ẹ sì pa wọ́n run, ẹ má ṣe pa wọ́n run pátápátá. Ya ẹ̀ka rẹ̀ kúrò, nítorí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kì í ṣe ti Olúwa.
11 He nui hoki te tinihanga o te whare o Iharaira raua ko te whare o Hura ki ahau, e ai ta Ihowa.
Ilé Israẹli àti ilé Juda ti jẹ́ aláìṣòdodo sí mi,” ni Olúwa wí.
12 Kua whakakahore ratou ki ta Ihowa, kua mea, ehara i a ia; e kore hoki te he e tae mai ki a tatou; e kore ano tatou e kite i te hoari, i te hemokai.
Wọ́n ti pa irọ́ mọ́ Olúwa; wọ́n wí pé, “Òun kì yóò ṣe ohun kan! Ibi kan kì yóò sì tọ̀ wá wá; àwa kì yóò sì rí idà tàbí ìyàn.
13 Ko nga poropiti he hau kau, kahore hoki he kupu i a ratou: ko enei mea ka pa ki a ratou.
Àwọn wòlíì wá dàbí afẹ́fẹ́, ọ̀rọ̀ kò sí nínú wọn. Nítorí náà, jẹ́ kí ohun tí wọ́n bá sọ ṣẹlẹ̀ sí wọn.”
14 Na reira tenei kupu a Ihowa, a te Atua o nga mano, Mo ta koutou korerotanga i tena kupu, tenei ahau te mea nei i aku kupu i roto i tou mangai hei ahi, ko tenei iwi hoki hei rakau, a ka pau ratou.
Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí: “Nítorí tí àwọn ènìyàn ti sọ àwọn ọ̀rọ̀ wọ̀nyí; Èmi yóò sọ ọ̀rọ̀ mi lẹ́nu wọn di iná, àti àwọn ènìyàn wọ̀nyí di igi tí yóò jórun.
15 Tenei ahau te kawe nei i tetahi iwi o tawhiti ki a koutou, e te whare o Iharaira, e ai ta Ihowa; he iwi kaha, he iwi nonamata riro, he iwi kahore nei koe e mohio ki tona reo, kahore ano hoki e marama ki tana e korero ai.
Háà, ẹ̀yin ilé Israẹli,” ni Olúwa wí, “Èmi yóò mú kí orílẹ̀-èdè láti ọ̀nà jíjìn dìde sí i yín Orílẹ̀-èdè àtijọ́ àti alágbára nì àwọn ènìyàn tí ìwọ kò mọ èdè rẹ̀, tí ọ̀rọ̀ rẹ̀ kò sì yé ọ.
16 Ko tana papa pere he urupa tuwhera, he tangata marohirohi katoa ratou.
Apó-ọfà rẹ sì dàbí isà òkú tí a ṣí gbogbo wọn sì jẹ́ akọni ènìyàn.
17 A ka pau i a ratou au hua e kotia ana, me tau taro, nga kai hei kainga ma au tama, ma au tamahine; ka pau i a ratou au hipi me au kau; ka pau i a ratou au waina me au piki; ka hautopea iho ki te hoari ou pa taiepa, au i whakawhirinaki ai.
Wọn yóò jẹ ìkórè rẹ àti oúnjẹ rẹ, àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti obìnrin, wọn yóò sì jẹ agbo àti ẹran rẹ, wọn yóò jẹ àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ. Pẹ̀lú idà ni wọn ó run ìlú tí ìwọ gbẹ́kẹ̀lé.
18 Ahakoa i aua ra ano, e ai ta Ihowa, e kore e whakapaua rawatia taku ki a koutou.
“Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì,” ni Olúwa wí, “Èmi kì yóò pa yín run pátápátá.
19 Na, ki te ki mai koutou a mua, He aha a Ihowa, to tatou Atua i mea ai i enei mea katoa ki a tatou? ko reira koe ki atu ai ki a ratou, Ka pena i a koutou kua whakarere na i ahau, kua mahi na ki nga atua ke i to koutou whenua, waihoki ka mahi kout ou ki nga tangata ke i te whenua ehara nei i a koutou.
Àti pé, nígbà tí àwọn ènìyàn bá sì béèrè wí pé, ‘Kí ni ìdí rẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run wa fi ṣe gbogbo èyí sí wa?’ Ìwọ yóò sì sọ fún wọn wí pé, ‘Ẹ̀yin ti kọ̀ mí sílẹ̀, ẹ sì ń sin ọlọ́run àjèjì ní ilẹ̀ yín. Nísinsin yìí, ẹ̀yin yóò máa sin àjèjì ní ilẹ̀ tí kì í ṣe tiyín.’
20 Whakaaturia tenei i roto i te whare o Hakopa, kia rangona ano i roto i a Hura; mea atu,
“Kéde èyí fún ilé Jakọbu, kí ẹ sì polongo rẹ̀ ní Juda.
21 Tena, whakarongo ki tenei, e te iwi wairangi kahore nei he ngakau, he kanohi nei o ratou, heoi kahore e kite, he taringa o ratou, a kahore e rongo.
Gbọ́ èyí, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìlọ́gbọ́n ènìyàn, tí ó lójú ti kò fi ríran tí ó létí ti kò fi gbọ́rọ̀.
22 Kahore ranei o koutou wehi ki ahau? e ai ta Ihowa; e kore ianei koutou e hopohopo ki toku aroaro? naku nei hoki i mea te onepu hei rohe ki te moana, he tikanga mau tonu, e kore ano e koni mai: ahakoa ngana noa ona ngaru, e kore e taea ta ratou; hamama noa, e kore ano e koni mai.
Kò ha yẹ kí ẹ bẹ̀rù mi?” ni Olúwa wí. “Kò ha yẹ kí ẹ̀yin ó wárìrì níwájú mi bí? Mo fi yanrìn pààlà òkun, èyí tí kò le è rékọjá rẹ̀ láéláé. Ìjì lè jà, kò le è borí rẹ̀; wọ́n le è bú, wọn kò le è rékọjá rẹ̀.
23 Ko tenei iwi ia, he tutu, he whakakeke o ratou ngakau; kua peka ke atu ratou, kua riro.
Ṣùgbọ́n, àwọn ènìyàn wọ̀nyí ní ọkàn líle àti ọkàn ọ̀tẹ̀, wọ́n ti yípadà, wọ́n sì ti lọ.
24 Kahore hoki a ratou kianga ake i roto i o ratou ngakau, Tena, kia wehi tatou ki a Ihowa, ki to tatou Atua, ko ia nei te kaihomai i te ua; i to mua, i to muri, i te wa e tika ai; nana nei i mau ai ki a tatou nga wiki i whakaritea mo te kotinga.
Wọn kò sọ fún ara wọn pé, ‘Ẹ jẹ́ ká a bẹ̀rù Olúwa Ọlọ́run wa, ẹni tí ó fún wa ní òjò àkọ́rọ̀ àti àrọ̀kúrò òjò ní ìgbà rẹ̀, tí ó fi wá lọ́kàn balẹ̀ nípa ìkórè ọ̀sẹ̀ déédé.’
25 Na o koutou he enei i puta ke ai, ko o koutou hara ano hei kaiponu atu i te pai i a koutou.
Àìṣedéédéé yín mú gbogbo nǹkan wọ̀nyí kúrò, ẹ̀ṣẹ̀ yín sì mú kí a fi nǹkan rere dù yín.
26 E kitea ana hoki he hunga kino i roto i taku iwi: titiro matatau mai ana ratou, me te mea he kaihopu manu e kupapa ana; kei te whakatakoto mahanga ratou, kei te hopu tangata.
“Láàrín ènìyàn mi ni ìkà ènìyàn wà tí ó wà ní ibùba bí ẹni tí ó ń dẹ ẹyẹ, àti bí àwọn tí ó ń dẹ pàkúté láti mú ènìyàn.
27 Kei te whare manu e ki ana i nga manu te rite o o ratou whare e ki tonu nei i te tinihanga: na reira ratou i nui ai, i whai taonga ai.
Bí àgò tí ó kún fún ẹyẹ, ilé wọn sì kún fún ẹ̀tàn; wọ́n ti di ọlọ́lá àti alágbára,
28 Tetere tonu ratou, towahiwahi ana; kua neke rawa ake ta ratou i nga mahi a te hunga kino: ko te whakawa, ko te whakawa a te pani, kahore i whakaritea e ratou, heoi kake tonu ratou; kahore hoki e whakatikaia e ratou te whakawa a nga rawakore.
wọ́n sanra wọ́n sì ń dán. Ìwà búburú wọn kò sì lópin; wọn kò bẹ̀bẹ̀ fún ẹjọ́ àwọn aláìní baba láti borí rẹ̀. Wọn kò jà fún ẹ̀tọ́ àwọn tálákà.
29 E kore ranei ahau e whai mahara ki enei mea? e ai ta Ihowa; e kore ranei toku wairua e rapu utu i te iwi penei?
Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n fún èyí bí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò wá gbẹ̀san ara mi lára orílẹ̀-èdè bí èyí bí?
30 Whakamiharo rawa, whakawehi rawa te mea e meatia ana ki te whenua;
“Nǹkan ìbànújẹ́ àti ohun ìtara ti ṣẹlẹ̀ ní ilẹ̀ náà.
31 E poropiti teka ana nga poropiti; a e whakahaere ana nga tohunga, ko ta ratou te tikanga; a pai tonu taku iwi ki te pena. Na ka pehea ra koutou i tona tukunga iho?
Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké, àwọn àlùfáà sì ń ṣe àkóso pẹ̀lú àṣẹ ara wọn, àwọn ènìyàn mi sì ní ìfẹ́ sí èyí, kí ni ẹ̀yin yóò ṣe ní òpin?

< Heremaia 5 >