< Heremaia 42 >

1 Katahi nga rangatira katoa o nga ope, ratou ko Hohanana tama a Karea, ko Tetania tama a Hohaia, ko te iwi katoa hoki, i te iti ki te rahi, ka haere mai,
Nígbà náà ní gbogbo àwọn olórí ogun àti Johanani ọmọkùnrin Karea àti Jesaniah ọmọkùnrin Hoṣaiah àti kékeré títí dé orí ẹni ńlá wá.
2 A ka mea ki a Heremaia poropiti, Tena, tukua atu ta matou inoi kia manaakitia ki tou aroaro; mau hoki e inoi mo matou ki a Ihowa, ki tou Atua, ara mo enei morehu katoa; he torutoru noa hoki matou o te tokomaha i toe iho, e kite na ou kanohi i a m atou:
Sí ọ̀dọ̀ Jeremiah wòlíì náà, wọ́n sì sọ fún un pé, “Jọ̀wọ́ gbọ́ ẹ̀bẹ̀ wa, kí o sì gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run rẹ fún gbogbo ìyókù yìí. Nítorí gẹ́gẹ́ bi ìwọ ṣe rí i nísinsin yìí pé a pọ̀ níye nígbà kan rí; ṣùgbọ́n báyìí àwa díẹ̀ la ṣẹ́kù.
3 Kia whakaaturia mai e Ihowa, e tou Atua, ki a matou te ara e haere ai matou, te mea e mahi ai matou.
Gbàdúrà pé kí Olúwa Ọlọ́run rẹ sọ ibi tí àwa yóò lọ fún wa àti ohun tí àwa yóò ṣe.”
4 Ano ra ko Heremaia poropiti ki a ratou, Kua rongo ahau ki a koutou; nana, ka inoi ahau ki a Ihowa, ki to koutou Atua, ka rite ki a koutou kupu na: a, ko nga kupu katoa e whakahokia mai e Ihowa ki a koutou, ka whakaaturia e ahau ki a koutou; e kor e tetahi kupu e kaiponuhia e ahau ki a koutou.
Wòlíì Jeremiah sì dáhùn wí pé, “Mo ti gbọ́. Èmi yóò gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run yín gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin ṣe béèrè. Èmi yóò sọ gbogbo ohun tí Olúwa bá sọ fún un yín, ń kò sì ní fi ohunkóhun pamọ́ fún un yín.”
5 Ano ra ko ratou ki a Heremaia, He pono, he tika hoki a Ihowa hei kaiwhakaatu mo ta tatou, ki te kahore e rite ta matou e mea ai ki nga kupu katoa e unga mai ai koe e Ihowa, e tou Atua, ki a matou.
Nígbà náà ni wọ́n sọ fún Jeremiah wí pé, “Kí Olúwa ṣe ẹlẹ́rìí òtítọ́ àti òdodo láàrín wa, bí àwa kò bá ṣe gẹ́gẹ́ bí gbogbo ohun tí Olúwa Ọlọ́run rẹ bá rán ọ láti sọ fún wa.
6 Ahakoa pai, ahakoa kino, ka rongo matou ki te reo o Ihowa, o to tatou Atua, ka unga nei koe e matou ki a ia; kia whai pai ai matou, ki te rongo matou ki te reo o Ihowa, o to tatou Atua.
Ìbá à ṣe rere, ìbá à ṣe búburú, àwa yóò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa, èyí tí àwa ń rán ọ sí, kí ó ba à lè dára fún wa. Nítorí pé àwa yóò gbọ́rọ̀ sí Olúwa Ọlọ́run wa.”
7 Na i te mutunga o nga ra kotahi tekau ka puta mai te kupu a Ihowa ki a Heremaia.
Lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́wàá, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá,
8 Katahi ia ka karanga ki a Hohanana tama a Karea, ratou ko ona hoa, ko nga rangatira katoa o nga ope, ki te iwi katoa hoki, ki te iti, ki te rahi,
O sì pe Johanani ọmọkùnrin Karea àti gbogbo àwọn olórí ogun tí wọ́n wà pẹ̀lú rẹ̀; àti gbogbo àwọn ènìyàn láti orí ẹni tí ó kéré dé orí ẹni ńlá.
9 A ka mea ki a ratou, Ko te kupu tenei a Ihowa, a te Atua o Iharaira, i unga nei ahau e koutou ki te whakatakoto i ta koutou inoi ki tona aroaro;
Ó sì wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn Israẹli wí: ‘Èyí ni ẹni tí ẹ̀yin ti rán láti gbé ẹ̀bẹ̀ yín lọ síwájú mi.
10 Ki te noho tonu koutou ki tenei whenua, katahi ahau ka hanga i a koutou, a kahore e wahi iho i a koutou, ka whakatokia hoki koutou e ahau, a kahore e hutia ake: no te mea e ripeneta ana ahau ki te kino kua oti nei i ahau te mea ki a koutou.
Bí ẹ̀yin bá gbé ní ilẹ̀ yìí, èmi yóò gbé e yín ró, n kò sí ní fà yín lulẹ̀, èmi yóò gbìn yín, n kì yóò fà yín tu nítorí wí pé èmi yí ọkàn padà ní ti ibi tí mo ti ṣe sí i yín.
11 Kaua e wehi i te kingi o Papurona, e wehingia na e koutou: kaua e wehi i a ia, e ai ta Ihowa; no te mea kei a koutou ahau hei whakaora i a koutou, hei tango i a koutou i roto i tona ringa.
Ẹ má ṣe bẹ̀rù ọba Babeli tí ẹ̀yin ń bẹ̀rù, báyìí ẹ má ṣe bẹ̀rù rẹ̀ ni Olúwa wí; nítorí tí èmi wà pẹ̀lú yín láti pa yín mọ́ àti láti gbà yín ní ọwọ́ rẹ̀.
12 A ka tukua atu aku mahi atawhai ki a koutou, kia atawhai ai ia i a koutou, a ka whakahoki i a koutou ki to koutou oneone.
Èmi yóò fi àánú hàn sí i yín, kí ó lè ṣàánú fún un yín, kí ó sì mú un yín padà sí ilẹ̀ yín.’
13 Tena ki te mea koutou, E kore matou e noho ki tenei whenua; a ka kore koutou e rongo ki te reo o Ihowa, o to koutou Atua;
“Ṣùgbọ́n sá, bí ẹ̀yin bá wí pé, ‘Àwa kò ní gbé ilẹ̀ yìí,’ ẹ̀yin ti ṣe àìgbọ́ràn sí Olúwa Ọlọ́run yín.
14 Ka mea, Kahore; engari ka haere matou ki te whenua o Ihipa, ki te wahi e kore ai matou e kite i te whawhai, e kore ai hoki e rongo i te tangi o te tetere, a e kore ai e hiakai ki te taro; a hei reira tatou noho ai:
Àti pé bí ẹ̀yin bá wí pé, ‘Bẹ́ẹ̀ kọ́, àwa yóò lọ gbé ní Ejibiti; níbi tí àwa kì yóò rí ìró ogunkógun, tí a kì yóò sì gbọ́ ìró fèrè, tí ebi oúnjẹ kì yóò sì pa wá, níbẹ̀ ni àwa ó sì máa gbé,’
15 Na kia rongo koutou aianei, e nga morehu o Hura, ki te kupu a Ihowa, Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano, a te Atua o Iharaira, Ki te maro tonu o koutou kanohi ki te haere ki Ihipa, a ka haere koutou ki reira noho ai;
nítorí náà, ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ìyókù Juda èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli wí: ‘Bí ẹ̀yin bá pinnu láti lọ sí Ejibiti láti lọ ṣe àtìpó níbẹ̀.
16 Na ka mau koutou i te hoari, e wehingia nei e koutou, ki reira, ki te whenua o Ihipa, a ka whaia tatatia koutou e te hemokai, e wehi na koutou, ki reira, ki Ihipa; a ka mate koutou ki reira.
Yóò sì ṣe, idà tí ẹ̀yin bẹ̀rù yóò sì lé e yín bá níbẹ̀; àti ìyanu náà tí ẹ̀yin ń bẹ̀rù yóò sì tẹ̀lé yín lọ sí Ejibiti àti pé ibẹ̀ ni ẹ̀yin yóò kú sí.
17 Na ka pena nga tangata katoa e naro ana o ratou kanohi ki te haere ki Ihipa ki reira noho ai; ka mate ratou i te hoari, i te hemokai, i te mate uruta: a e kore tetahi o ratou e toe, e mawhiti i te kino e takina mai e ahau ki runga ki a ratou.
Nítorí náà, gbogbo àwọn tí ó ti pinnu láti ṣe àtìpó ní Ejibiti ni yóò ti ipa idà kú, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn kò sì ní jẹ́ kí ẹnikẹ́ni nínú wọn yè tàbí sá àsálà nínú ibi tí èmi yóò mú wá sórí wọn.’
18 Ko te kupu hoki tenei a Ihowa o nga mano, a te Atua o Iharaira; Ka rite ki taku ringihanga i toku riri, i toku weriweri, ki runga ki nga tangata o Hiruharama, ka pena ano taku ringihanga i toku weriweri ki runga ki a koutou, ina tae koutou ki Ih ipa: a hei kohukohutanga, hei hahanitanga; a e kore koutou e kite i tenei wahi a muri atu.
Báyìí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Gẹ́gẹ́ bí èmi ti da ìbínú àti ìrunú síta sórí àwọn tí ó ń gbé ní Jerusalẹmu, bẹ́ẹ̀ ni ìrunú mi yóò dà síta sórí yín, nígbà tí ẹ̀yin bá lọ sí Ejibiti. Ẹ̀yin ó sì di ẹni ègún àti ẹni ẹ̀gàn àti ẹ̀sín, ẹ̀yin kì yóò sì rí ibí yìí mọ́.’
19 Kua puaki ta Ihowa kupu mo koutou, E nga morehu o Hura, Kaua e haere ki Ihipa: kia tino mohio koutou kua oti te whakaatu e ahau ki a koutou i tenei ra.
“Ẹ̀yin yòókù Juda, Olúwa ti sọ fún un yín pé, ‘Kí ẹ má ṣe lọ sí Ejibiti.’ Ẹ mọ èyí dájú, èmi kìlọ̀ fún un yín lónìí,
20 Kua tinihanga hoki koutou ki o koutou na wairua ano; i unga hoki koutou i ahau ki a Ihowa, ki to koutou Atua, i ki mai, Inoi mo matou ki a Ihowa, ki to tatou Atua; a, ko nga mea katoa e korerotia e Ihowa, e to tatou Atua, mau e whakaatu ki a mat ou, a ka mahia e matou.
pé àṣìṣe ńlá gbá à ni ẹ̀yin ṣe nígbà tí ẹ̀yin rán mi sí Olúwa Ọlọ́run yín pé, ‘Gbàdúrà sí Olúwa Ọlọ́run wa fún wa; sọ fún wa gbogbo ohun tí ó bá sọ, àwa yóò sì ṣe é.’
21 Na kua whakaaturia nei e ahau ki a koutou i tenei ra; otira kihai koutou i rongo ki te reo o Ihowa, o to koutou Atua, i nga mea katoa i unga ai ahau e ai ki a koutou.
Mo ti sọ fún un yín lónìí, ṣùgbọ́n síbẹ̀ ẹ̀yin kò tí ì gbọ́ ohùn Olúwa Ọlọ́run yín, àti gbogbo ohun tí ó rán mi láti sọ fún un yín.
22 Ko tenei, kia tino mohio koutou, tera koutou e mate i te hoari, i te hemokai, i te mate uruta, ki te wahi i hiahia ai koutou kia haere ki reira noho ai.
Ǹjẹ́ nísinsin yìí ẹ mọ èyí dájú pé, ẹ̀yin yóò kú nípa idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn níbikíbi tí ẹ̀yin bá fẹ́ lọ láti ṣe àtìpó.”

< Heremaia 42 >