< Heremaia 23 >

1 Aue, te mate mo nga hepara e whakakorekore nei, e whakamarara nei i aku hipi i hepara ai, e ai ta Ihowa.
“Ègbé ni fún àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń tú agbo ẹran mi ká tí ó sì ń pa wọ́n run!” ni Olúwa wí.
2 Mo reira ko te kupu tenei a Ihowa, a te Atua o Iharaira mo nga hepara e whangai nei i taku iwi, Kua whakamararatia e koutou aku hipi, aia atu ana ratou, kihai hoki i tirotirohia e koutou; nana, ka whiua koutou e ahau mo te kino o a koutou mahi, e ai ta Ihowa.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli sọ ní ti àwọn olùṣọ́-àgùntàn tí ń darí àwọn ènìyàn mi: “Nítorí tí ẹ̀yin tú agbo ẹran mi ká, tí ẹ lé wọn dànù tí ẹ̀yin kò sì bẹ̀ wọ́n wò. Èmi yóò jẹ yín ní yà nítorí nǹkan búburú tí ẹ ti ṣe,” ni Olúwa wí.
3 A ka huihuia mai e ahau nga toenga o aku hipi i nga whenua katoa i peia atu ai ratou e ahau, ka whakahokia mai hoki ratou ki o ratou puninga, a ka hua ratou, ka tini.
“Èmi Olúwa tìkára mi yóò kó ìyókù agbo ẹran mi jọ láti inú gbogbo orílẹ̀-èdè tí mo ti lé wọn, Èmi yóò mú wọn padà sínú pápá oko wọn, níbẹ̀ ni wọn ó ti bí sí i, tí wọn ó sì pọ̀ sí i.
4 A ka whakaarahia ake e ahau etahi kepara mo ratou, mana ratou e whangai: a e kore ratou e wehi a muri ake nei, e kore e pawera, e kore hoki tetahi e ngaro atu, e ai ta Ihowa.
Èmi ó wá olùṣọ́-àgùntàn fún wọn, tí yóò darí wọn, wọn kì yóò bẹ̀rù tàbí dààmú, bẹ́ẹ̀ ni ọ̀kan kì yóò sọnù,” ni Olúwa wí.
5 Nana, kei te haere mai nga ra, e ai ta Ihowa, e whakaarahia ai e ahau he Manga tika mo Rawiri, a ka kingi ia, he kingi, a ka mahi i runga i te whakaaro nui, ka whakarite hoki i te whakawa, i te tika ki te whenua.
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò gbé ẹ̀ka òdodo dìde fún Dafidi, ọba tí yóò lo ìjọba pẹ̀lú ọgbọ́n tí yóò sì ṣe òdodo àti ohun tí ó yẹ lórí ilẹ̀ náà.
6 I ona ra ka whakaorangia a Hura, ka noho humarie a Iharaira: a ko tona ingoa tenei e karangatia ai ia, Ko Ihowa to tatou tika.
Ní ọjọ́ rẹ̀ ni a ó gba Juda là, Israẹli yóò sì máa gbé ní aláìléwu. Èyí ni orúkọ tí a ó fi máa pè é: Olúwa Òdodo wa.
7 No reira, na, kei te haere mai nga ra, e ai ta Ihowa, e kore ai e korerotia, E ora ana a Ihowa nana nei i kawe mai nga tama a Iharaira i te whenua o Ihipa;
Nítorí náà, ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí ènìyàn kì yóò tún wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa wà láààyè tí ó mú àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò ní ilẹ̀ Ejibiti.’
8 Engari, E ora ana a Ihowa nana nei i kawe mai, nana nei i arahi mai nga uri o te whare o Iharaira i te whenua ki te raki, i nga whenua katoa ano i peia atu ai ratou e ahau; a ka noho ratou ki to ratou oneone.
Ṣùgbọ́n wọn yóò máa wí pé, ‘Dájúdájú Olúwa ń bẹ tí ó mú irú-ọmọ ilé Israẹli wá láti ilẹ̀ àríwá àti láti àwọn ilẹ̀ ibi tí mo tí lé wọn lọ,’ wọn ó sì gbé inú ilẹ̀ wọn.”
9 Na mo nga poropiti. Kei te maru toku ngakau i roto i ahau, ngaueue ana oku wheua katoa; e rite ana ahau ki te tangata haurangi, ki te tangata kua mate i te waina; he whakaaro hoki ki a Ihowa, he whakaaro ki ana kupu tapu.
Nípa ti àwọn wòlíì èké. Ọkàn mi ti bàjẹ́ nínú mi, gbogbo egungun mi ni ó wárìrì. Èmi dàbí ọ̀mùtí ènìyàn, bí ọkùnrin tí ọtí wáìnì ń pa; nítorí Olúwa àti àwọn ọ̀rọ̀ mímọ́ rẹ̀.
10 Kei te kapi hoki te whenua i te tangata puremu; kei te tangi hoki te whenua, he mea mo te kanga; kua maroke nga wahi kai o te koraha; a ko to ratou rerenga he kino, ko to ratou kaha, kahore i tika.
Ilẹ̀ náà kún fún panṣágà ènìyàn; nítorí ègún, ilẹ̀ náà gbẹ, àwọn koríko orí aṣálẹ̀ ilẹ̀ náà rọ. Àwọn wòlíì tẹ̀lé ọ̀nà búburú, wọ́n sì ń lo agbára wọn lọ́nà àìtọ́.
11 No te mea ko te poropiti, ko te tohunga, kua poke ngatahi raua: ae ra, kua kitea e ahau to ratou kino i roto i toku whare, e ai ta Ihowa.
“Wòlíì àti àlùfáà kò gbé ìgbé ayé ìwà-bí-Ọlọ́run; kódà nínú tẹmpili mi ni mo rí ìwà búburú wọn,” ni Olúwa wí.
12 Mo reira ka rite to ratou ara ki a ratou ki nga wahi pahekeheke i roto i te pouri: ka aia atu ratou, a ka taka ki reira: ka kawea atu hoki e ahau he kino ki runga ki a ratou, ko te tau hoki e tirotirohia ai ratou, e ai ta Ihowa.
“Nítorí náà, ọ̀nà wọn yóò di yíyọ́, a ó lé wọn jáde sínú òkùnkùn; níbẹ̀ ni wọn yóò ṣubú. Èmi yóò mú ìdààmú wá sórí wọn, ní ọdún tí a jẹ wọ́n ní ìyà,” ni Olúwa wí.
13 A kua kite ahau i te wairangi i roto i nga poropiti o Hamaria; na Paara ta ratou poropititanga, a whakapohehetia ana e ratou taku iwi, a Iharaira.
“Láàrín àwọn wòlíì Samaria, Èmi rí ohun tí ń lé ni sá. Wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ Baali wọ́n sì mú Israẹli ènìyàn mi ṣìnà.
14 Kei nga poropiti ano hoki o Hiruharama, kua kitea e ahau tetahi mea whakahouhou rawa; e puremu ana ratou, a ka haere i runga i te teka, a e whakakahangia ana e ratou nga ringa o nga kaimahi o te kino, e kore rawa ai tetahi e tahuri mai i tona ki no; ki ahau kua rite ratou katoa ki Horoma, a ko nga tangata o reira, koia ano kei o Komora.
Àti láàrín àwọn wòlíì Jerusalẹmu, èmi ti rí ohun búburú. Wọ́n ṣe panṣágà, wọ́n sì ń ṣèké. Wọ́n fún àwọn olùṣe búburú ní agbára, tó bẹ́ẹ̀ tí kò sí ẹnìkan tí ó yípadà kúrò nínú ìwà búburú rẹ̀. Gbogbo wọn dàbí Sodomu níwájú mi, àti àwọn ènìyàn olùgbé rẹ̀ bí Gomorra.”
15 Mo reira ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano mo nga poropiti: Nana, ka whangaia ratou e ahau ki te taru kawa, a ka whakainumia ratou ki te wai kawa: no te mea i ahau atu i nga poropiti o Hiruharama te takahi tapu puta noa i te whenua katoa.
Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Ọlọ́run Alágbára wí ní ti àwọn wòlíì: “Èmi yóò mú wọn jẹ oúnjẹ kíkorò, wọn yóò mu omi májèlé nítorí láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì Jerusalẹmu ni àìwà-bí-Ọlọ́run ti tàn ká gbogbo ilẹ̀.”
16 Ko te kupu tenei a Ihowa o nga mano, Kei whakarongo ki nga kupu a nga poropiti e poropiti na ki a koutou: e ako ana ratou i a koutou ki te wairangi: e korero ana ratou i te kite a to ratou ake ngakau, a ehara i te mea na te mangai o Ihowa.
Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí: “Ẹ má ṣe fi etí sí àsọtẹ́lẹ̀ tí àwọn wòlíì èké ń sọ fún un yín. Wọ́n ń kún inú ọkàn yín pẹ̀lú ìrètí asán. Wọ́n ń sọ ìran láti ọkàn ara wọn, kì í ṣe láti ẹnu Olúwa.
17 E mea tonu ana ratou ki te hunga e whakahawea ana ki ahau, Kua ki mai a Ihowa, Ka mau te rongo ki a koutou; a, ki te hunga katoa e haere ana i runga i nga tikanga pakeke o o ratou ngakau, e mea ana ratou, E kore te kino e tae mai ki a koutou.
Wọ́n ń sọ fún àwọn tí ó ń gàn mí pé, ‘Olúwa ti wí pé, ẹ̀yin ó ní àlàáfíà.’ Wọ́n sì wí fún gbogbo àwọn tí ó rìn nípa agídí ọkàn rẹ̀ pé, ‘Kò sí ìpalára kan tí yóò ṣẹlẹ̀ sí yín.’
18 Ko wai oti i tu i runga i to Ihowa whakaaro, e kite ai, e rongo ai ranei ki tana kupu? ko wai i mahara ki taku kupu, i rongo hoki?
Ṣùgbọ́n èwo nínú wọn ni ó dúró nínú ìgbìmọ̀ Olúwa láti rí i tàbí gbọ́ ọ̀rọ̀ rẹ̀? Ta ni ó gbọ́ tí ó sì fetí sí ọ̀rọ̀ náà?
19 Nana, kua puta te tukauati i a Ihowa, koia ano ko tona riri, ae ra, he tukauati powaiwai: tera e pakaru ki runga ki te upoko o te hunga kino.
Wò ó, afẹ́fẹ́ Olúwa yóò tú jáde pẹ̀lú ìbínú à fẹ́ yíká ìjì yóò fẹ́ sí orí àwọn olùṣe búburú.
20 E kore e hoki to Ihowa riri, kia oti ra ano, kia whakapumautia ra ano e ia nga whakaaro o tona ngakau: i nga ra whakamutunga ka tino marama koutou.
Ìbínú Olúwa kì yóò yẹ̀ títí tí yóò sì fi mú èrò rẹ̀ ṣẹ, ní àìpẹ́ ọjọ́, yóò yé e yín yékéyéké.
21 Kihai ahau i unga i enei poropiti, heoi rere ana ratou; kihai ahau i korero ki a ratou, heoi kei te poropiti ratou.
Èmi kò rán àwọn wòlíì wọ̀nyí síbẹ̀ wọ́n lọ pẹ̀lú ọ̀rọ̀ wọn. Èmi kò tilẹ̀ bá wọn sọ̀rọ̀, síbẹ̀ wọ́n sọ àsọtẹ́lẹ̀.
22 Otiia me i tu ratou i runga i toku whakaaro, kua meinga e ratou taku iwi kia rongo ki aku kupu, kua whakahokia mai e ratou i to ratou ara kino, i te kino hoki o a ratou mahi.
Ṣùgbọ́n ì bà ṣe pé wọn dúró nínú ìgbìmọ̀ mi, wọn ìbá ti kéde ọ̀rọ̀ mi fún àwọn ènìyàn mi. Wọn ìbá ti wàásù ọ̀rọ̀ mi fun àwọn ènìyàn wọn ìbá ti yípadà kúrò nínú ọ̀nà àti ìṣe búburú wọn.
23 He Atua tata ianei ahau, e ai ta Ihowa, a ehara i te Atua i tawhiti?
“Ǹjẹ́ Ọlọ́run tòsí nìkan ni Èmi bí?” ni Olúwa wí, “kì í sì í ṣe Ọlọ́run ọ̀nà jíjìn.
24 E taea ranei e tetahi te huna i a ia ki nga wahi ngaro, e kore ai ia e kitea e ahau? e ai ta Ihowa. He teka ianei kapi tonu i ahau te rangi me te whenua? e ai ta Ihowa.
Ǹjẹ́ ẹnikẹ́ni lè sá pamọ́ sí ibi kọ́lọ́fín kan, kí èmi má ba a rí?” ni Olúwa wí. “Ǹjẹ́ èmi kò ha a kún ọ̀run àti ayé bí?” ni Olúwa wí.
25 Kua rongo ahau i nga kupu a nga poropiti, e poropiti teka na i runga i toku ingoa, e mea na, He moe naku, he moe naku.
“Mo ti gbọ́ gbogbo ohun tí àwọn wòlíì èké tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ní orúkọ mi ń sọ. Wọ́n sọ wí pé, ‘Mo lá àlá! Mo lá àlá!’
26 Kia pehea te roa o te mau o tenei i roto i te ngakau o nga poropiti, e poropiti teka na; ara o nga poropiti, e poropiti na i te tinihanga o to ratou ngakau?
Títí di ìgbà wo ni èyí yóò fi máa tẹ̀síwájú ni ọkàn àwọn wòlíì èké wọ̀nyí tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ ìtànjẹ ọkàn wọn?
27 E whakaaro na, ma a ratou moe e korerotia na e ratou ki tona hoa, ki tona hoa, ka meinga ai taku iwi kia wareware ki toku ingoa, kia pera me o ratou matua i wareware nei ki toku ingoa, i mea nei ki a Paara.
Wọ́n rò wí pé àlá tí wọ́n ń sọ fún ara wọn yóò mú kí àwọn ènìyàn mi gbàgbé orúkọ mi, gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe gbàgbé orúkọ mi nípa sí sin òrìṣà Baali.
28 Ko te poropiti he moe nei tana, me korero e ia te moe; a ko te tangata i a ia taku kupu, kia pono tana korero i taku kupu. He aha oti ta te papapa ki te witi? e ai ta Ihowa.
Jẹ́ kí wòlíì tí ó bá lá àlá sọ àlá rẹ̀, ṣùgbọ́n jẹ́ kí ẹni tí ó ní ọ̀rọ̀ mí sọ ọ́ ní òtítọ́. Kí ni koríko gbígbẹ ní í ṣe nínú ọkà?” ni Olúwa wí.
29 He teka ianei e rite ana taku kupu ki te ahi? e ai ta Ihowa; ki te hama e wahi nei i te kamaka a mongamonga noa?
“Ọ̀rọ̀ mi kò ha a dàbí iná?” ni Olúwa wí, “àti bí òòlù irin tí ń fọ́ àpáta túútúú?
30 Mo reira, na, hei hoariri ahau mo nga poropiti, e ai ta Ihowa, e tahae nei i aku kupu i tona hoa, i tona hoa.
“Nítorí náà, èmi lòdì sí àwọn wòlíì ni,” Olúwa wí, “Tí ń jí ọ̀rọ̀ tí ó yẹ kí ó ti ọ̀dọ̀ mi wá lò lọ́dọ̀ ara wọn.
31 Nana, hei hoariri ahau mo nga poropiti, e ai ta Ihowa, mo te hunga e whakamahi nei i o ratou arero, e ki nei, E mea ana ia.
Bẹ́ẹ̀,” ni Olúwa wí, “Èmi lòdì sí àwọn wòlíì tí wọ́n lo ahọ́n wọn káàkiri, síbẹ̀ tí wọ́n ń sọ wí pé, ‘Olúwa wí.’
32 Nana, hei hoariri ahau, e ai ta Ihowa, mo te hunga e poropiti ana i nga moe teka, a korerotia ana e ratou, whakapohehetia ana e ratou taku iwi ki a ratou korero teka, ki ta ratou whakapehapeha wairangi: otiia ehara ratou i ahau i unga, i whakaha u ranei; e kore rawa hoki tenei iwi e whai pai i a ratou, e ai ta Ihowa.
Nítòótọ́, mo lòdì sí àwọn tí ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ nípa àlá èké,” ni Olúwa wí. “Wọ́n ń sọ bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì ń mú àwọn ènìyàn mi ṣìnà nípa onírúurú èké wọn, síbẹ̀ èmi kò rán wọn tàbí yàn wọ́n. Wọn kò sì ran àwọn ènìyàn wọ̀nyí lọ́wọ́ bí ó ti wù kí ó kéré mọ,” ni Olúwa wí.
33 A, ki te ui tenei iwi, ki a koe, te poropiti, te tohunga ranei, ki te mea, Tena koa ta Ihowa pikaunga? katahi koe ka ki atu ki a ratou, E tae te pikaunga! Ka maka atu koutou e ahau, e ai ta Ihowa.
“Nígbà tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, tàbí wòlíì tàbí àlùfáà bá bi ọ́ léèrè wí pé, ‘Kí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa?’ Sọ fún wọn wí pé, ‘Ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ wo? Èmi yóò pa yín tì ni Olúwa wí.’
34 Na, ko te poropiti, ko te tohunga, ko te iwi ranei, e mea ana, Ko te pikaunga a Ihowa, ka whiua e ahau taua tangata, ratou ko tona whare.
Bí wòlíì tàbí àlùfáà tàbí ẹnikẹ́ni bá sì gbà wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’ Èmi yóò fi ìyà jẹ ọkùnrin náà àti gbogbo agbo ilé rẹ̀.
35 Ko te kupu tenei ma koutou ki tona hoa, ki tona hoa, ki tona teina, ki tona tuakana, Tena koa te kupu i whakahokia mai e Ihowa? a, I pehea mai a Ihowa?
Èyí ni ohun tí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín ń sọ fún ọ̀rẹ́ àti ará ilé rẹ̀: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa sọ?’
36 Kati hoki ta koutou whakahua i te pikaunga a Ihowa; no te mea ko te kupu ake a tenei, a tenei hei pikaunga mana; kua whakarereketia hoki e koutou nga kupu a te Atua, ora, a Ihowa o nga mano, a to tatou Atua.
Ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò gbọdọ̀ dárúkọ ọ̀rọ̀ ‘ìjìnlẹ̀ Olúwa’ mọ́, nítorí pé ọ̀rọ̀ oníkálùkù ènìyàn di ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ rẹ̀. Nítorí náà, ẹ̀yin ń yí ọ̀rọ̀ Ọlọ́run alààyè, Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run wa padà.
37 Ko tau tenei e korero atu ai ki te poropiti, He aha te whakautu a Ihowa ki a koe? ko tenei hoki, I pehea mai a Ihowa?
Èyí ni ohun tí ẹ̀yin ń sọ fún wòlíì: ‘Kí ni ìdáhùn Olúwa sí ọ́?’ Tàbí ‘Kí ni ohun tí Olúwa bá ọ sọ?’
38 Engari ki te mea koutou, Ko te pikaunga a Ihowa; na ko te kupu tenei a Ihowa; Mo ta koutou korero i tena kupu, Ko te pikaunga a Ihowa, a kua unga tangata ahau ki a koutou, hei mea, Kaua koutou e ki, Ko te pikaunga a Ihowa;
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀yin ń sọ wí pé, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ èyí ni ohun tí Olúwa sọ, Ẹ̀yin ń lo ọ̀rọ̀ yìí, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa,’ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé mo sọ fún un yín láti má ṣe lò ó mọ́, ‘Èyí ni ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ Olúwa.’
39 Mo reira, na, ka wareware rawa ahau ki a koutou, ka akiritia atu ano koutou i toku aroaro, me te pa i hoatu e ahau ki a koutou ko o koutou matua.
Nítorí náà, Èmi yóò gbàgbé yín, bẹ́ẹ̀ ni n ó lé e yín kúrò níwájú mi pẹ̀lú àwọn ìlú tí mo fi fún un yín àti àwọn baba yín.
40 Ka utaina hoki e ahau he ingoa kino ki runga ki a koutou, he mea mau tonu, he whakama hoki e mau tonu ana, a e kore e wareware.
Èmi yóò sì mú ìtìjú ayérayé wá sí orí yín, ìtìjú tí kò ní ní ìgbàgbé.”

< Heremaia 23 >