< Heremaia 14 >

1 Ko te kupu a Ihowa i puta mai ki a Heremaia, he mea mo te tauraki.
Èyí ni ọ̀rọ̀ Olúwa sí Jeremiah nípa ti àjàkálẹ̀-ààrùn:
2 Kei te tangi a Hura, ngehe kau ona kuwaha, kua noho ki te whenua he mangu ona kakahu; kua kake te aue o Hiruharama ki runga.
“Juda káàánú, àwọn ìlú rẹ̀ kérora wọ́n pohùnréré ẹkún fún ilẹ̀ wọn, igbe wọn sì gòkè lọ láti Jerusalẹmu.
3 Na ka unga o ratou ariki i a ratou tamariki ririki ki nga awa: ka tae ratou ki nga poka, kahore e kite wai; ka hoki me a ratou oko, tahanga kau: ka whakama ratou, ka numinumi, ka hipoki i o ratou mahunga.
Àwọn ọlọ́lá ènìyàn rán àwọn ìránṣẹ́ wọn lọ bu omi, wọ́n lọ sí ìdí àmù ṣùgbọ́n wọn kò rí omi. Wọ́n padà pẹ̀lú ìkòkò òfìfo; ìrẹ̀wẹ̀sì àti àìnírètí bá wọn, wọ́n sì bo orí wọn.
4 I te ngatata o te oneone, kahore ano nei hoki he ua ki runga ki te whenua, ka whakama nga kaiparau, ka hipoki i o ratou mahunga.
Ilẹ̀ náà sán nítorí pé kò sí òjò ní ilẹ̀ náà; ìrètí àwọn àgbẹ̀ di òfo, wọ́n sì bo orí wọn.
5 Ae ra, ko te hata ano, whanau ana ia i waenga parae, a whakarerea ake e ia tana kuao, no te mea kahore he tarutaru.
Kódà, abo àgbọ̀nrín tí ó wà lórí pápá fi ọmọ rẹ̀ tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ bí sílẹ̀, torí pé kò sí koríko.
6 Na ka tu nga kaihe mohoao i runga i nga wahi tiketike, ka kihakiha ano he kirehe mohoao; matawaia ana o ratou kanohi, kahore hoki he otaota.
Àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ igbó dúró lórí òkè òfìfo wọ́n sì ń mí ẹ̀fúùfù bí ìkookò ojú wọn kò ríran nítorí pé kò sí koríko jíjẹ.”
7 Ahakoa whakaatu noa o matou kino i to matou he, e mahi koe, e Ihowa, kia mahara hoki ki tou ingoa: kua tini nei hoki o matou tahuritanga ketanga, kua hara matou ki a koe.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ẹ̀ṣẹ̀ wa jẹ́rìí lòdì sí wa, wá nǹkan kan ṣe sí i Olúwa, nítorí orúkọ rẹ. Nítorí ìpadàsẹ́yìn wa ti pọ̀jù, a ti ṣẹ̀ sí ọ.
8 E koe, e te tumanako a Iharaira, e tona kaiwhakaora i te wa o te raru, he aha koe i noho ai i te whenua ano he manene, i rite ai ki te tangata haere e peka ana ki tetahi moenga mona i te po?
Ìrètí Israẹli; ìgbàlà rẹ lásìkò ìpọ́njú, èéṣe tí ìwọ dàbí àlejò ní ilẹ̀ náà bí arìnrìn-àjò tí ó dúró fún bí òru ọjọ́ kan péré?
9 He aha koe i rite ai ki te tangata e ketekete kau ana, ki te marohirohi e kore nei e kaha ki te whakaora? kei waenganui ano ia koe i a matou, e Ihowa, kua huaina tou ingoa mo matou; kaua hoki matou e whakarerea.
Èéṣe tí ìwọ dàbí ẹni tí a dààmú, bí jagunjagun tí kò le ran ni lọ́wọ́? Ìwọ wà láàrín wa, Olúwa, orúkọ rẹ ni a sì ń pè mọ́ wa; má ṣe fi wá sílẹ̀.
10 Ko te kupu tenei a Ihowa ki tenei iwi, He pena tonu to ratou matenui ki te taihaere; kihai i kaiponuhia o ratou waewae; no reira kahore a Ihowa e manako ki a ratou; ka mahara ia aianei ki o ratou he, a ka whiu i o ratou hara.
Báyìí ni Olúwa sọ nípa àwọn ènìyàn wọ̀nyí: “Wọ́n fẹ́ràn láti máa rìn kiri; wọn kò kó ọkàn wọn ní ìjánu. Nítorí náà Olúwa kò gbà wọ́n; yóò wá rántí ìwà búburú wọn báyìí, yóò sì fi ìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn jẹ wọ́n.”
11 A ka mea a Ihowa ki ahau, Kaua e inoi mo tenei iwi ki te pai mo ratou.
Nígbà náà ni Olúwa sọ fún mi pé, “Má ṣe gbàdúrà fún àlàáfíà àwọn ènìyàn wọ̀nyí.
12 Ka nohopuku ratou, e kore ahau e rongo ki ta ratou karanga; ka whakaekea e ratou te tahunga tinana me te whakahere, e kore ahau e manako ki a ratou; engari ka poto ratou i ahau, i te hoari, i te hemokai, i te mate uruta.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n gbààwẹ̀, èmi kò ní tẹ́tí sí igbe wọn. Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé wọ́n rú ẹbọ sísun àti ẹbọ ìyẹ̀fun, èmi ò nígbà wọ́n. Dípò bẹ́ẹ̀, èmi ó fi idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn pa wọ́n run.”
13 Ano ra ko ahau, Aue, e te Ariki, e Ihowa, nana, ko nga poropiti te mea nei ki a ratou, E kore koutou e kite i te hoari, e kore ano te hemokai e pa ki a koutou; engari maku e mea kia tuturu rawa te mau o te rongo ki a koutou i tenei wahi.
Ṣùgbọ́n mo sọ pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè. Àwọn wòlíì ń sọ fún wọn pé, ‘Ẹ kò ni rí idà tàbí ìyàn. Dájúdájú èmi ó fún yín ní àlàáfíà tí yóò tọ́jọ́ níbí yìí?’”
14 Ano ra ko Ihowa ki ahau, Kei te poropiti teka nga poropiti i runga i toku ingoa: kihai ratou i unga e ahau, kihai ratou i whakahaua e ahau, kihai hoki ahau i korero ki a ratou: he kitenga teka ta ratou e poropiti na ki a koutou, he whakaaro ki n ga tohu, he mea horihori, he mea tinihanga na o ratou ngakau.
Nígbà náà Olúwa sọ fún mi pé, “Àwọn wòlíì ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ èké ní orúkọ mi. Èmi kò rán wọn, tàbí yàn wọ́n tàbí bá wọn sọ̀rọ̀. Ìran èké ni wọ́n ń rí sí i yín. Àsọtẹ́lẹ̀ èké ni wọ́n ń sọ fún un yín nípa ìran ìrírí, àfọ̀ṣẹ, ìbọ̀rìṣà àti ìtànjẹ ọkàn wọn.
15 Mo reira ko te kupu tenei a Ihowa mo nga poropiti e poropiti nei i runga i toku ingoa, he hunga kihai i unga e ahau, i a ratou e mea nei, E kore te hoari, te hemokai ranei e pa ki tenei whenua: Ka poto ena poropiti i te hoari, i te hemokai.
Nítorí náà, èyí ni Olúwa sọ nípa àwọn wòlíì tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ lórúkọ mi. Èmi kò rán wọn, síbẹ̀ wọ́n sì ń sọ pé, ‘Idà kan tàbí ìyàn, kì yóò dé ilẹ̀ yìí.’ Àwọn wòlíì kan náà yóò parẹ́ nípa idà àti ìyàn.
16 Na, ko te iwi ki a ia nei ta ratou poropititanga, ka akiritia ki nga ara o Hiruharama i te ngaunga a te hemokai, a te hoari; kahore hoki he tangata hei tanu i a ratou, i a ratou, i a ratou wahine, i a ratou tama, i a ratou tamahine; no te mea ka ringihia e ahau to ratou kino ki runga ki a ratou.
Bẹ́ẹ̀ sì ni àwọn ènìyàn tí wọ́n ń sọ àsọtẹ́lẹ̀ fún ni a ó lé sí òpópónà Jerusalẹmu torí idà àti ìyàn. Wọn kò ní i rí ẹni tí yóò sìn wọ́n tàbí ìyàwó wọn, àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn. Èmi yóò mú ìdààmú tí ó yẹ bá ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin wọn.
17 Na me korero e koe tenei kupu ki a ratou, Kia hirere iho te roimata o oku kanohi i te po, i te ao, kaua hoki e mutu; no te mea he nui te pakaru i pakaru ai te tamahine a taku iwi, mamae rawa te patunga.
“Kí ìwọ kí ó sì sọ ọ̀rọ̀ yìí fún wọn pé: “‘Jẹ́ kí ojú mi kí ó sun omijé ní ọ̀sán àti ní òru láìdá; nítorí tí a ti ṣá wúńdíá, ọmọ ènìyàn mi ní ọgbẹ́ ńlá pẹ̀lú lílù bolẹ̀.
18 Ki te haere ahau ki te parae, nana, ko nga tupapaku a te hoari! ki te tomo ahau ki te pa, nana, ko te hunga e mate ana i te hemokai! ko te poropiti hoki raua tahi ko te tohunga kei te haereere noa iho i te whenua a kahore e mohio.
Bí mo bá lọ sí orílẹ̀-èdè náà, Èmi yóò rí àwọn tí wọ́n fi idà pa. Bí mo bá lọ sí ìlú ńlá, èmi rí àwọn tí ìyàn ti sọ di aláàrùn. Wòlíì àti Àlùfáà ti lọ sí ilẹ̀ tí wọn kò mọ̀.’”
19 Kua paopao rawa ranei koe ki a Hura? kua whakarihariha ranei tou wairua ki Hiona? He aha koe i patu ai i a matou, te ai he mahunga mo o matou mate? I tatari matou ki te rongo mau, heoi kahore he pai; ki te wa e mahu ai, na ko te raruraru.
Ṣé o ti kọ Juda sílẹ̀ pátápátá ni? Ṣé o ti ṣá Sioni tì? Èéṣe tí o fi pọ́n wa lójú tí a kò fi le wò wá sàn? A ń retí àlàáfíà ṣùgbọ́n ohun rere kan kò tí ì wá, ní àsìkò ìwòsàn ìpayà là ń rí.
20 Tenei matou, e Ihowa, te whaki nei i to matou kino, i te he o o matou matua: kua hara hoki matou ki a koe.
Olúwa, a jẹ́wọ́ ìwà ibi wa àti àìṣedéédéé àwọn baba wa; lóòótọ́ ni a ti ṣẹ̀ sí ọ.
21 Kaua e whakarihariha ki a matou, whakaaro ki tou ingoa; kaua e whakaititia te torona o tou kororia; kia mahara, kaua e whakataka tau kawenata ki a matou.
Nítorí orúkọ rẹ má ṣe kórìíra wa; má ṣe sọ ìtẹ́ ògo rẹ di àìlọ́wọ̀. Rántí májẹ̀mú tí o bá wa dá kí o má ṣe dà á.
22 Kei roto ranei i nga mea horihori a nga tauiwi tetahi hei mea kia ua? ma nga rangi ranei e homai nga ua nehu? he teka ianei ko koe ia, e Ihowa, e to matou Atua? na reira matou ka tatari ki a koe; nau hoki i hanga enei mea katoa.
Ǹjẹ́ èyíkéyìí àwọn òrìṣà yẹ̀yẹ́ tí àwọn orílẹ̀-èdè le ṣe kí òjò rọ̀? Ǹjẹ́ àwọsánmọ̀ fúnra rẹ̀ rọ òjò bí? Rárá, ìwọ ni, Olúwa Ọlọ́run wa. Torí náà, ìrètí wa wà lọ́dọ̀ rẹ, nítorí pé ìwọ lo ń ṣe gbogbo nǹkan wọ̀nyí.

< Heremaia 14 >