< Ehekiera 35 >

1 I puta mai ano te kupu a Ihowa ki ahau, i mea,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá:
2 E te tama a te tangata, anga atu tou mata ki Maunga Heira, poropititia te he mo reira,
“Ọmọ ènìyàn kọjú sí òkè Seiri; sọtẹ́lẹ̀ sí i,
3 Mea atu hoki ki a ia, Ko te kupu tenei a te Ariki, a Ihowa; Nana, hei hoariri ahau mou, e Maunga Heira, a ka totoro atu toku ringa ki a koe, ka ururua rawa koe i ahau, ka meinga hoki hei miharotanga.
kí o sì sọ wí pé, ‘Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmí lòdì sí ọ, òkè Seiri, Èmi yóò sì na ọwọ́ mi síta ní ìlòdì sí ọ, èmi yóò sì mú kí ó di ahoro.
4 Ko ou pa ka tuhea i ahau, a hei ururua koe, a ka mohio koe ko Ihowa ahau.
Èmi yóò pa àwọn ìlú rẹ run, ìwọ yóò sì di ahoro. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
5 No te mea he mauahara mau tonu tou, a kua tukua e koe nga tama a Iharaira ki te kaha o te hoari i te wa o to ratou aitua, i te wa o te he i te mutunga.
“‘Nítorí ìwọ dá ààbò bo ọ̀tẹ̀ àtayébáyé, tí ìwọ sì fi Israẹli lé idà lọ́wọ́, ní àsìkò ìdààmú wọn, ní àsìkò tí ìjìyà wọn dé góńgó,
6 Mo reira, e ora ana ahau, e ai ta te Ariki, ta Ihowa, ka mahia koe e ahau hei mea mo te toto, ka whaia ano koe e te toto; kihai na koe i kino ki te toto, na ka whaia koe e te toto.
nítorí náà bi mo ti wà láààyè, ni Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò fi ọ kalẹ̀ fún ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ. Níwọ́n ìgbà tí ìwọ kò ti kórìíra ìtàjẹ̀ sílẹ̀, ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò sì lépa rẹ.
7 Heoi ka meinga e ahau a Maunga Heira hei matakitakinga, hei ururua; a ka hatepea atu e ahau te tangata e tika ana na reira, te tangata ano e hoki mai ana.
Èmi yóò mú kí òkè Seiri di ahoro; ọ̀fọ̀ gbogbo àwọn tí ó ń lọ tí ó ń bọ̀ ní èmi yóò gé kúrò lára rẹ.
8 A ka whakakiia e ahau ona maunga ki ona tupapaku: a, ko te hunga e patua ki te hoari, ka hinga ki ou pukepuke, ki ou awaawa, ki ou rerenga wai katoa.
Èmi yóò fi àwọn tí a pa kún orí òkè rẹ, àwọn tí a fi idà pa yóò ṣubú ní orí òkè rẹ, àti ní àárín àwọn òkè rẹ.
9 Ka ururua koe i ahau a ake ake; e kore ano ou pa e nohoia, a ka mohio koutou ko Ihowa ahau.
Èmi yóò mú kí ó di ahoro títí láé, kò ní sí olùgbé ní ìlú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.
10 Na, kua mea na koe, Ko enei iwi e rua, ko enei whenua e rua moku, mo tatou tonu hoki; i te mea kei reira nei ano a Ihowa;
“‘Nítorí tí ìwọ sọ pé, “Àwọn orílẹ̀-èdè àti ilẹ̀ méjì wọ̀nyí yóò jẹ́ tiwa, àwa yóò sì gbà wọ́n ní ìní,” bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, Èmi Olúwa wà níbẹ̀,
11 Mo reira, e ora ana ahau, e ai ta te Ariki, ta Ihowa, ko taku mahi ka rite ki tou riri, ki tou hae, i hae ai koe i a koe i mauahara ra ki a ratou; a ka whakakitea atu ahau ki a ratou, ina rite i ahau te whakawa mou.
nítorí náà níwọ̀n ìgbà tí mo ti wà láààyè, ní Olúwa Olódùmarè wí, èmi yóò hùwà sí ọ ní ìbámu pẹ̀lú ìbínú àti owú tí o fihàn nínú ìkórìíra rẹ sí wọn, èmi yóò fi ara mi hàn ní àárín wọn, nígbà tí mo bá ṣe ìdájọ́ rẹ.
12 Na ka mohio koe ko Ihowa ahau, a kua rangona e ahau au kohukohu katoa i korerotia e koe mo nga maunga o Iharaira, i a koe i ki ra, Kua ururua, kua homai hei kai ma tatou.
Nígbà náà ni ìwọ yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti gbọ́ gbogbo ohun ẹ̀gàn tí ìwọ ti sọ lòdì sí àwọn òkè Israẹli náà. Ìwọ wí pé, “A sọ wọ́n di ahoro, a sì fi wọ́n fún wa láti run.”
13 A kua whakakake mai o koutou mangai ki ahau, kua whakamaha i a koutou kupu moku: kua rongo ahau.
Ìwọ lérí sí mi, ó sì sọ̀rọ̀ lòdì sí mí láìsí ìdádúró, èmi sì gbọ́ ọ.
14 Ko te kupu tenei a te Ariki, a Ihowa; A te wa e koa ai te whenua katoa, ka ururua koe i ahau.
Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nígbà tí gbogbo ayé bá ń yọ̀, èmi yóò mú kí ó di ahoro.
15 I koa na koe ki te kainga o te whare o Iharaira, kua ururua na, ka pena ano ahau ki a koe: ka ururua koe, e Maunga Heira, e Eroma katoa, ae ra, katoa; a ka mohio ratou ko Ihowa ahau.
Nítorí pé ìwọ ń yọ̀ nígbà tí ìní ilé Israẹli di ahoro, bẹ́ẹ̀ gẹ́gẹ́ ni èmi yóò ṣe hùwà sí ọ. Ìwọ yóò di ahoro, ìwọ òkè Seiri, ìwọ àti gbogbo ará Edomu. Nígbà náà, wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”

< Ehekiera 35 >