< Matio 16 >

1 Nimb’ama’e mb’eo o Fariseo naho Tsadokeo han­tsaka fañahy aze, hanolora’e viloñe boak’ andindiñe ao.
Àwọn Farisi àti àwọn Sadusi wá láti dán Jesu wò. Wọ́n ní kí ó fi àmì ńlá kan hàn àwọn ní ojú ọ̀run.
2 Hoe ty natoi’ Iesoà: Ry soa­miatrekeo, Ie hariva, anoe’areo ty hoe: Kanao mena i like­rañey, hazava ty hamaray,
Ó dá wọn lóhùn pé, “Nígbà tí ó bá di àṣálẹ́, ẹ ó sọ pé, ‘Ìbá dára kí ojú ọ̀run pọ́n.’
3 ie maraindray, hoe nahareo: Ho avy anito i orañey fa milodolodo i like­rañey. Ie fohi’ areo o fañè ty tarehe’ i likerañeio, akore te tsy rendre’ areo ty lili’ o sà-o.
Ní òwúrọ̀, ‘Ẹ̀yin yóò wí pé ọjọ́ kì yóò dára lónìí, nítorí ti ojú ọ̀run pọ́n, ó sì ṣú dẹ̀dẹ̀,’ ẹ̀yin àgàbàgebè, ẹ̀yin le sọ àmì ojú ọ̀run, ṣùgbọ́n ẹ̀yin kò le mọ àmì àwọn àkókò wọ̀nyí.
4 Mipay viloñe ty tariratse tsereheñe toy, fe tsy hitoloram-biloñe naho tsy ty vilo’ i Jona mpitoky; vaho nisitake re, nienga mb’eo.
Ìran búburú aláìgbàgbọ́ yìí ń béèrè àmì àjèjì mélòó kàn ni ojú sánmọ̀, ṣùgbọ́n a kí yóò fún ẹnìkankan ní àmì bí kò ṣe àmì Jona.” Nígbà náà ni Jesu fi wọ́n sílẹ̀, ó sì bá tirẹ̀ lọ.
5 Ie nivotrake añ’olon-driake eo t’i Iesoà le hoe re amo mpiama’eo, Halankaño mofo, vaho nijon-dakañe mindre amo mpiama’eo, fe nihaliño o mpiama’eo ty hivaty mofo.
Nígbà tí wọ́n dé apá kejì adágún, àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ ṣàkíyèsí pé wọ́n ti gbàgbé láti mú àkàrà kankan lọ́wọ́.
6
Jesu sì kìlọ̀ fún wọn pé, “Ẹ kíyèsára, ẹ sì ṣọ́ra, ní ti ìwúkàrà àwọn Farisi àti àwọn Sadusi.”
7
Wọ́n ń sọ eléyìí ni àárín ara wọn wí pé, “Nítorí tí àwa kò mú àkàrà lọ́wọ́ ni.”
8 le hoe t’ Iesoà am’iereo: Ino ty itsakorea’areo te tsy nivaty mofo?
Nígbà tí ó gbọ́ ohun ti wọ́n ń sọ, Jesu béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Ẹ̀yin onígbàgbọ́ kékeré, èéṣe tí ẹ̀yin ń dààmú ara yín pé ẹ̀yin kò mú oúnjẹ lọ́wọ́?
9 Tsy tiahi’ areo hao i mofo limey naho i lahilahy efats’ arivo rey vaho ty hamaro’ o mozete nisisao?
Tàbí ọ̀rọ̀ kò yé yín di ìsinsin yìí? Ẹ̀yin kò rántí pé mo bọ́ ẹgbẹ̀rún márùn-ún ènìyàn pẹ̀lú ìṣù àkàrà márùn-ún àti iye agbọ̀n tí ẹ kójọ bí àjẹkù?
10 ndra i mofo fito’ indaty efats’arivo rey, naho ty hamaro i haron-kiseñe rinambe’areo rezay?
Ẹ kò sì tún rántí ìṣù méje tí mo fi bọ́ ẹgbàajì ènìyàn àti iye agbọ̀n tí ẹ̀yín kójọ?
11 Aa le maharendreha te tsy mofo sotra i vinolakoy fe inao ty itaroñako: Itaò ty sata’ o Fariseo naho Tsadokeo.
Èéha ṣe tí kò fi yé yín pé èmi kò sọ̀rọ̀ nípa ti àkàrà? Lẹ́ẹ̀kan sí i, mo wí fún yín, ẹ ṣọ́ra fún ìwúkàrà àwọn Farisi àti ti Sadusi.”
12 Aa le napota’iareo te tsy ty lalivay mofo i nitsarae’ey, fa ty fañanara’ o Fariseoo naho o Tsadokeo.
Nígbà náà ni ó ṣẹ̀ṣẹ̀ wáyé wọn pé, kì í ṣe nípa ti ìwúkàrà ní ó sọ wí pé kí wọ́n kíyèsára, bí kò ṣe tí ẹ̀kọ́ àwọn Farisi àti Sadusi.
13 Ie nandoake an-tane Siria naho an-tane’ Filofe añe t’i Iesoà, le hoe ty ontane’e amo mpiama’eo: Ino ty saontsie’ ondatio ahy?
Nígbà tí Jesu sì dé Kesarea-Filipi, ó bi àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Ta ni àwọn ènìyàn ń fi Ọmọ Ènìyàn pè?”
14 Le hoe iereo ama’e: Ty ila’e: i Jaona Mpandipotse; ty ila’e, i Elia; vaho ty ila’e, i Jere­mia’ ndra ty raike amo mpitokio.
Wọ́n dá a lóhùn pé, “Àwọn kan ni Johanu onítẹ̀bọmi ni, àwọn mìíràn wí pé, Elijah ni, àwọn mìíràn wí pé, Jeremiah ni, tàbí ọ̀kan nínú àwọn wòlíì.”
15 Aa hoe t’i Iesoà tam’ iereo: Ia ka ty anoe’ areo ahy?
“Ṣùgbọ́n ẹyin ń kọ?” Ó bi í léèrè pé, “Ta ni ẹ̀yin ń fi mi pè?”
16 Tinoi’ i Simona ty hoe: Ihe i Norizañey, Anak’ Andrianañahare veloñe nivotrake ami’ty voatse toy.
Simoni Peteru dáhùn pé, “Ìwọ ni Kristi náà, Ọmọ Ọlọ́run alààyè.”
17 Hoe t’i Iesoà tama’e: Haha irehe Simona Ana’ i Jaona amy te tsy nofotse naho lio ty nampibentatse ama’o fa t’i Raeko andindìñe ao.
Jesu sì wí fún un pé, “Alábùkún fún ni ìwọ Simoni ọmọ Jona, nítorí ẹran-ara àti ẹ̀jẹ̀ kọ́ ló fi èyí hàn bí kò ṣe Baba mi tí ó ń bẹ ní ọ̀run.
18 Hoe iraho ama’o: Vongam-bato irehe, naho haoreko ami’ty lamilamy toy ty anjombam-pitalahoako. ze tsy hahafitroara’ o lalam-bein-tsikeokeokeo. (Hadēs g86)
Èmi wí fún ọ, ìwọ ni Peteru àti pé orí àpáta yìí ni èmi yóò kọ́ ìjọ mi lé, àti ẹnu-ọ̀nà ipò òkú kì yóò lè borí rẹ̀. (Hadēs g86)
19 Le hatoloko azo i lahin-dakilem-pifehean-dikerañey; ze fehè’o an-tane atoy le fa nifeheñe an­dindìñe ao, vaho ze hahà’o an-tane atoy le fa nihahàñe andindìñ’ao.
Èmi yóò fún ní àwọn kọ́kọ́rọ́ ìjọba Ọ̀run; ohun tí ìwọ bá dè ní ayé, òun ni a ó dè ní ọ̀run. Ohunkóhun tí ìwọ bá sì tú ní ayé yìí, a ó sì tú ní ọ̀run.”
20 Hinatahata’e amy zao o mpiama’eo ty tsy hita­lily am’ondatio te ie i Norizañey.
Nígbà náà ó kìlọ̀ fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé wọn kò gbọdọ̀ sọ fún ẹnikẹ́ni pé Òun ni Kristi náà.
21 Namototse nampalange amo mpiama’eo amy zao t’Iesoà t’ie tsy mahay tsy homb’e Ierosaleme mb’eo hijale ami’ty hatsivokara’ ty maro boak’ amo mpisoroñeo naho amo roandria’ ondatio ampara’ te havetrake, f’ie hatroatse ami’ty andro faha-telo.
Láti ìgbà yìí lọ, Jesu bẹ̀rẹ̀ sí ṣàlàyé fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ kedere nípa lílọ sí Jerusalẹmu láti jẹ ọ̀pọ̀ ìyà lọ́wọ́ àwọn àgbàgbà, àwọn olórí àlùfáà àti àwọn akọ̀wé, kí a sì pa òun, àti ní ọjọ́ kẹta, kí ó sì jíǹde.
22 Natola’ i Petera le nendaha’e ami’ty hoe: Lonike te ho lavits’ Azo izay, Talè
Peteru mú Jesu sí ẹ̀gbẹ́ kan, ó bẹ̀rẹ̀ sí í bá a wí pé, “Kí a má rí i Olúwa! Èyí kì yóò ṣẹlẹ̀ sí Ọ!”
23 Nitolike t’i Iesoà, le nitala­hara’e naho nanao ty hoe: Soike, ty mpañìnje, ko zehare’o; tsy haoñe’o ty tsaran’ Añahare, fa o reha’ ondatio.
Jesu pa ojú dà, ó sì wí fún Peteru pé, “Kúrò lẹ́yìn mi, Satani! Ohun ìkọ̀sẹ̀ ni ìwọ jẹ́ fún mi; ìwọ kò ro ohun tí i ṣe ti Ọlọ́run, bí kò ṣe èyí ti ṣe ti ènìyàn.”
24 Le hoe t’i Iesoà amo mpi­ama’eo: Ze te hañorik’ ahy, soa re te hitety vatañe, hijiny i hatae ajaley, toe hamoe aiñe, vaho hañorik’ ahy.
Nígbà náà ni Jesu wí fún àwọn ọmọ-ẹ̀yìn rẹ̀ pé, “Bí ẹnikẹ́ni bá fẹ́ tọ̀ mí lẹ́yìn, kí ó sẹ́ ara rẹ̀, kí ó sì gbé àgbélébùú rẹ̀, kí ó sì máa tọ̀ mí lẹ́yìn.
25 Ze te handrombake ty fiai’e ro hamoe aze ty amako, fe ze mamoe ty havelo’e ami’ty voatse toy ty amako ro handrombake aze ho ami’ty havelo’ ty voatse ho avy.
Nítorí ẹnikẹ́ni tí ó bá fẹ́ gba ẹ̀mí rẹ̀ là, yóò sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bá sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù nítorí mi, yóò rí i.
26 Ino ty tombo’e ho a ondatio te fonga azo’e ty voatse toy, vaho mamoe’ay kitro katroke? Fampitsalohañe soa ho a ondatio hao ty hahazoa’e o raha momoke henaneo, hanolora’e ty fiai’e hizakà’ i tsikeokeokey?
Èrè kí ni ó jẹ́ fún ènìyàn bí ó bá jèrè gbogbo ayé yìí, tí ó sì sọ ẹ̀mí rẹ̀ nù? Tàbí kí ni ènìyàn yóò fi dípò ẹ̀mí rẹ̀?
27 Fa hitotsake atoy i Anan’ Añaharey ami’ty engen-dRae’e an-dindiñe ao rekets’ o anjeli’eo hanambe ondatio sindre ty amo sata’eo.
Nítorí Ọmọ Ènìyàn yóò wá nínú ògo baba rẹ pẹ̀lú àwọn angẹli rẹ̀, nígbà náà ni yóò sì san án fún olúkúlùkù gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ rẹ̀.
28 Eka! to t’itaroñako te, tsy handia havilasy o ila’e mijohañe etoañe, ampara’ te isa’ iareo mitots­ake eo i Anak’ Andrianañaharey am-pifehea’ey ao.
“Lóòótọ́ ni mo wí fún yín. Ẹlòmíràn wà nínú àwọn tí ó wà níhìn-ín yìí, tí kì yóò ri ikú títí wọn ó fi rí Ọmọ Ènìyàn tí yóò máa bọ̀ ní ìjọba rẹ̀.”

< Matio 16 >