< Jaona 17 >

1 Ie nitsarae’ Iesoà, le niandrandra mb’andikerañe ey, nanao ty hoe: O Aba, fa tondroke ty ora; rengeo t’i Ana’o, handrengea’e Azo.
Nǹkan wọ̀nyí ni Jesu sọ, ó sì gbé ojú rẹ̀ sókè ọ̀run, ó sì wí pé, “Baba, wákàtí náà dé, yin ọmọ rẹ lógo, kí ọmọ rẹ kí ó lè yìn ọ́ lógo pẹ̀lú.
2 Fa nimea’o lily re hifehe ze kila nofotse, soa te ho tolora’e haveloñe nainai’e ze hene natolo’o aze. (aiōnios g166)
Gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti fún un ní àṣẹ lórí ènìyàn gbogbo, kí ó lè fi ìyè àìnípẹ̀kun fún gbogbo àwọn tí ó fi fún un. (aiōnios g166)
3 Zao o haveloñe nainai’eo, t’ie ho fohi’ iereo ry Andrianañahare tokañe to, naho Iesoà Norizañe nahitri’oy. (aiōnios g166)
Ìyè àìnípẹ̀kun náà sì ni èyí, kí wọn kí ó lè mọ ìwọ nìkan Ọlọ́run òtítọ́, àti Jesu Kristi, ẹni tí ìwọ rán. (aiōnios g166)
4 Fa nandrengeako an-tane atoy vaho nihenefako i nampitoloñe’o Ahiy.
Èmi ti yìn ọ́ lógo ní ayé: èmi ti parí iṣẹ́ tí ìwọ fi fún mi láti ṣe.
5 O Aba itoloro engeñe añila’o eo henaneo amy engeñe nindrezan-tika taolo’ ty fifotora’ ty voatse toiy.
Ǹjẹ́ nísinsin yìí, Baba, ṣe mí lógo pẹ̀lú ara rẹ, ògo tí mo ti ní pẹ̀lú rẹ kí ayé kí ó tó wà.
6 Fa nampahafohineko ondaty natolo’o ahy boak’ ami’ty voatse toio ty tahina’o, ie nifanaña’o, naho natolo’o ahiko vaho nambena’ iereo o tsara’oo.
“Èmi ti fi orúkọ rẹ hàn fún àwọn ènìyàn tí ìwọ ti fún mi láti inú ayé wá, tìrẹ ni wọ́n ti jẹ́, ìwọ sì ti fi wọ́n fún mi; wọ́n sì ti pa ọ̀rọ̀ rẹ mọ́.
7 Fa rendre’ iereo henaneo te boak’ ama’o ze hene natolo’o ahy,
Nísinsin yìí, wọ́n mọ̀ pé ohunkóhun gbogbo tí ìwọ ti fi fún mi, láti ọ̀dọ̀ rẹ wá ni.
8 ie natoloko o saontsy nimea’o ahikoo, naho rinambe’ iereo, naho rendre’ iereo to te boak’ ama’o iraho vaho antofa’ iereo te Ihe ro nañitrik’ ahy.
Nítorí ọ̀rọ̀ tí ìwọ fi fún mi, èmi ti fi fún wọn, wọ́n sì ti gbà á, wọ́n sì ti mọ̀ nítòótọ́ pé, lọ́dọ̀ rẹ ni mo ti jáde wá, wọ́n sì gbàgbọ́ pé ìwọ ni ó rán mi.
9 Ihalaliako; tsy ho ami’ty voatse toy ty ihalaliako, fa ho amo natolo’o ahikoo amy t’ie azo.
Èmi ń gbàdúrà fún wọn, èmi kò gbàdúrà fún aráyé, ṣùgbọ́n fún àwọn tí ìwọ ti fi fún mi; nítorí pé tìrẹ ni wọ́n í ṣe.
10 Kila azo o ahikoo, naho ahiko o azoo; vaho nahazoako engeñe.
Tìrẹ sá à ni gbogbo ohun tí í ṣe tèmi, àti tèmi sì ni gbogbo ohun tí í ṣe tìrẹ, a sì ti ṣe mí lógo nínú wọn.
11 Tsy ami’ty voatse toy ka iraho, fe ami’ty voatse toy o retoañe, vaho homb’ ama’o mb’eo iraho. Ry Aba masiñe, tambozoro an-tahina’o o natolo’o ahikoo, soa t’ie ho raike manahake itikañe.
Èmi kò sí ní ayé mọ́, àwọn wọ̀nyí sì ń bẹ ní ayé, èmi sì ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ. Baba mímọ́, pa àwọn tí o ti fi fún mi mọ́, ní orúkọ rẹ, kí wọn kí ó lè jẹ́ ọ̀kan, àní gẹ́gẹ́ bí àwa.
12 Izaho nimpiam’ iereo, le nambenako an-tahina’o o natolo’o ahikoo; ni­tam­bozoreko o natolo’o ahikoo, tsy ia ty nipoke naho tsy i anan-kamomohañey hampañeneke o Sokitse Masiñeo.
Nígbà tí mo wà pẹ̀lú wọn ní ayé, mo pa wọ́n mọ́ ní orúkọ rẹ; àwọn tí ìwọ fi fún mi, ni mo ti pamọ́, ẹnìkan nínú wọn kò sọnù bí kò ṣe ọmọ ègbé; kí ìwé mímọ́ kí ó le ṣẹ.
13 Mb’ama’o mb’eo iraho henaneo; naho taroñeko ami’ty voatse toy o entañe zao, handiforañe am’iereo o haehakoo.
“Ṣùgbọ́n nísinsin yìí èmi sì ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ, nǹkan wọ̀nyí ni mo sì ń sọ ní ayé, kí wọn kí ó lè ní ayọ̀ mi ní kíkún nínú àwọn tìkára wọn.
14 Fa natoloko iareo o tsara’oo le niheje’ ty voatse toy, amy t’ie tsy mpiami’ ty voatse toy, hambañe amy te izaho tsy mpiami’ ty voatse toy.
Èmi ti fi ọ̀rọ̀ rẹ fún wọn; ayé sì ti kórìíra wọn, nítorí tí wọn kì í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ bí èmi kì í ti í ṣe ti ayé.
15 Tsy ihalaliako te hakareñe ami’ty voatse toy iereo, fa t’ie ho kalañeñe ami’ty raty.
Èmi kò gbàdúrà pé, kí ìwọ kí ó mú wọn kúrò ní ayé, ṣùgbọ́n kí ìwọ kí ó pa wọ́n mọ́ kúrò nínú ibi.
16 Tsy mpiama’ ty voatse toy iereo, hambañe amy te izaho tsy mpiami’ ty voatse toy.
Wọn kì í ṣe ti ayé, gẹ́gẹ́ bí èmi kì í ti í ṣe ti ayé.
17 Ampiavaho an-katò iereo; o tsara’oo ro to.
Sọ wọ́n di mímọ́ nínú òtítọ́, òtítọ́ ni ọ̀rọ̀ rẹ.
18 Hambañe ami’ty nañiraha’o ahy mb’ami’ty voatse toy, ty nañitrifako iareo mb’ami’ty voatse toy.
Gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti rán mi wá sí ayé, bẹ́ẹ̀ ni èmi sì rán wọn sí ayé pẹ̀lú.
19 Ie ro añamasiñako vatañe, hañavaheko iareo añami’ty hatò.
Èmi sì ya ara mi sí mímọ́ nítorí wọn, kí a lè sọ àwọn tìkára wọn pẹ̀lú di mímọ́ nínú òtítọ́.
20 Tsy ho a iretoañe avao o ihalaliakoo, fa ho amo mbe hiato amako ami’ ty tsara’ iareoo;
“Kì sì í ṣe kìkì àwọn wọ̀nyí ni mo ń gbàdúrà fún, ṣùgbọ́n fún àwọn pẹ̀lú tí yóò gbà mí gbọ́ nípa ọ̀rọ̀ wọn.
21 soa te ho raike iaby iereo, hambañe amy te amako irehe Aba, naho ama’o iraho, vaho ho raik’ aman-tikañe iereo, hatokisa’ ty voatse toy te nañitrik’ ahy irehe.
Kí gbogbo wọn kí ó lè jẹ́ ọ̀kan; gẹ́gẹ́ bí ìwọ, Baba, ti jẹ́ nínú mi, àti èmi nínú rẹ, kí àwọn pẹ̀lú kí ó lè jẹ́ ọ̀kan nínú wa, kí ayé kí ó lè gbàgbọ́ pé, ìwọ ni ó rán mi.
22 Fa natoloko iareo i engeñe natolo’o ahikoy, soa t’ie ho raike, hambañe amy te itika ro raike:
Ògo tí ìwọ ti fi fún mi ni èmi sì ti fi fún wọn; kí wọn kí ó lè jẹ́ ọ̀kan, gẹ́gẹ́ bí àwa ti jẹ́ ọ̀kan.
23 Izaho am’iereo, naho Ihe amako, hamonirañe iareo ho raike; soa te ho fohi’ ty voatse toy te nañitrik’ ahy irehe vaho nikoko iareo, manahake ty fikokoa’o ahy.
Èmi nínú wọn, àti ìwọ nínú mi, kí a lè ṣe wọ́n pé ní ọ̀kan; kí ayé kí ó lè mọ̀ pé, ìwọ ni ó rán mi, àti pé ìwọ sì fẹ́ràn wọn gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti fẹ́ràn mi.
24 O Aba, salalaeko te hindre amako ami’ty hitoerako o natolo’o ahikoo, hahaoniñe i engeñe natolo’o ahiy, amy t’ie nikokoa’o taolo’ ty nañoreña’o ty voatse toy.
“Baba, èmi fẹ́ kí àwọn tí ìwọ fi fún mi, kí ó wà lọ́dọ̀ mi, níbi tí èmi gbé wà; kí wọn lè máa wo ògo mi, tí ìwọ ti fi fún mi, nítorí ìwọ sá à fẹ́ràn mi síwájú ìpilẹ̀ṣẹ̀ ayé.
25 Ry Aba vantañe, ihe tsy nifohi’ ty voatse toy, fe fohiko, naho fohi’ iretoañe te Ihe ro nañitrik’ ahy,
“Baba olódodo, ayé kò mọ̀ ọ́n; ṣùgbọ́n èmi mọ̀ ọ́n, àwọn wọ̀nyí sì mọ̀ pé ìwọ ni ó rán mi.
26 naho nampahafohineko iareo i tahina’oy, mbore hampandrendreheko, soa te ho am’ iareo i fikokoañe nikokoa’o ahiy vaho izaho am’ iareo.
Mo ti sọ orúkọ rẹ di mí mọ̀ fún wọn, èmi ó sì sọ ọ́ di mí mọ̀: kí ìfẹ́ tí ìwọ fẹ́ràn mi, lè máa wà nínú wọn, àti èmi nínú wọn.”

< Jaona 17 >