< Isaia 4 >
1 Amy andro zay, ho fihine’ ty rakemba fito ty lahilahy, hanao ty hoe: Ty mahakama’ay avao ty ho kamae’ay, naho ty saro’ay avao ty hiombea’ay; fe angao ho tokaveñe ami’ty tahina’o zahay, hañafahañe ty hasalara’ay.
Ní ọjọ́ náà, obìnrin méje yóò dì mọ́ ọkùnrin kan yóò sì wí pé, “Àwa ó máa jẹ oúnjẹ ara wa a ó sì pèsè aṣọ ara wa; sá à jẹ́ kí a máa fi orúkọ rẹ̀ pè wá. Mú ẹ̀gàn wa kúrò!”
2 Ho fanjàka naho hanañ’engeñe ty tora-mionjo’ Iehovà amy andro zay, vaho ho fisengeañe naho volonahe’ ty nibotitsike am’Israele ty voka’ i taney.
Ní ọjọ́ náà, ẹ̀ka Olúwa yóò ní ẹwà àti ògo, èso ilẹ̀ náà yóò sì jẹ́ ìgbéraga àti ògo àwọn ti ó sálà ní Israẹli.
3 Ho tondroke te hatao miavake ze sehanga’e amy Tsione ao naho ze honka’e am’ Ierosalaime ao, eka, ze hene sinokitse ho veloñe e Ierosalaime ao,
Àwọn tí ó ṣẹ́kù ní Sioni, àwọn tí o kù ní Jerusalẹmu, ni a ó pè ní mímọ́, orúkọ àwọn ẹni tí a kọ mọ́ àwọn alààyè ní Jerusalẹmu.
4 ie fa sinasa’ i Talè amo anak’ampela’ Israeleo ty haleora’e; naho fa nimongore’e ty lio’ Ierosalaime boak’ añ’ate’e ao ami’ty arofon-jaka naho ami’ty arofom-piforehetañe.
Olúwa yóò wẹ ẹ̀gbin àwọn obìnrin Sioni kúrò yóò sì fọ gbogbo àbàwọ́n ẹ̀jẹ̀ kúrò ní Jerusalẹmu pẹ̀lú ẹ̀mí ìdájọ́ àti ẹ̀mí iná.
5 Le hanoe’ Iehovà ambone’ ze akiba ambohi’ i Tsione eo naho ambone’ o firimboña’eo ty rahoñe an-katoeñe te handro, vaho ty fireandreañ’ afo milebaleba te haleñe; le ho ey ty lafike ambone’ o engeñe iabio.
Lẹ́yìn náà, Olúwa yóò dá sórí òkè Sioni àti sórí i gbogbo àwọn tí ó péjọpọ̀ síbẹ̀, kurukuru èéfín ní ọ̀sán àti ìtànṣán ọ̀wọ́-iná ní òru, lórí gbogbo ògo yìí ni ààbò yóò wà.
6 Le ho eo ka ty bandrabandra naho antoandro amy hatrevohañey, naho fipalirañe vaho fitampinañe ami’ty tio-bey naho amo orañeo.
Èyí ni yóò jẹ́ ààbò àti òjìji kúrò lọ́wọ́ ooru ọ̀sán, àti ààbò òun ibi ìsádi kúrò lọ́wọ́ ìjì àti òjò.