< Isaia 21 >

1 Ty nibangoeñe i ­fatram-bei’ i riakeiy: Manahake ty famaoha’ o tio-bey tatimoo, ie miboak’ an-dratraratra hirik’ an-tane mampangebahebak’ añe.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan aginjù lẹ́bàá Òkun. Gẹ́gẹ́ bí ìjì líle ti í jà kọjá ní gúúsù, akógunjàlú kan wá láti aginjù, láti ilẹ̀ ìpayà.
2 Naboak’ amako ty aroñaroñe mampioremeñe: Ty mpamañahy mamañahy, ty mpamaoke mamaoke. Mionjona ry Elame! Miarikoboña, ry Maday! Fa hene nampitsiñeko o fiselekaiñañeo.
Ìran tí a ń fojú ṣọ́nà fún ni a ti fihàn mí ọlọ̀tẹ̀ ti tu àṣírí, fọ́lé fọ́lé ti kẹ́rù. Elamu kojú ìjà! Media ti tẹ̀gùn! Èmi yóò mú gbogbo ìpayínkeke dópin, ni ó búra.
3 Aa le mikoritoke avao ty vaniako; mamihiñe ahy ty fitsongoañe, manahake ty fitsongon’ ampela mañèñe; mikoretse iraho le tsy mahatsanoñe, miroreke tsy mahafañente.
Pẹ̀lú èyí, ìrora mu mi lára gírígírí, ìrora gbá mi mú, gẹ́gẹ́ bí i ti obìnrin tí ń rọbí, mo ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n nítorí ohun tí mo gbọ́, ọkàn mi pòruurù nípa ohun tí mo rí.
4 Mifejofejo ty troko; mampirevendreveñ’ahiko ty tahotse; nivalike ho fineveneverañe i palipalitsieñe nisalalaeko.
Ọkàn mí dàrú, ẹ̀rù mú jìnnìjìnnì bá mi, ìmọ́lẹ̀ tí mo ti ń fẹ́ ẹ́ rí ti wá di ìpayà fún mi.
5 Nihalankañeñe i fandambañañey, nalamake i tihiy, nikama naho ninoñe; Miongaha ry roandriañeo, hosoro o fikalan-defoñeo.
Wọ́n tẹ́ tábìlì, wọ́n tẹ́ ẹní àtẹ́ẹ̀ká, wọ́n jẹ, wọ́n mu! Dìde nílẹ̀, ẹ̀yin ọmọ-aládé, ẹ fi òróró kún asà yín!
6 Fa zao ty nafè’ i Talè amako: Akia, ajadoño ty mpijilo; adono hitalily ze talake’e.
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Lọ, kí o bojúwòde kí o sì wá sọ ohun tí ó rí.
7 Nahaisake firimboñañe re reketse mpiningi-tsoavala ki-roe roe, mpijòm-borìke naho mpitoboke an-drameva; mitsendreñe amy zao re, mitsatsike.
Nígbà tí ó bá rí àwọn kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin, àwọn tó ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ tàbí àwọn tí ó gun ìbákasẹ, jẹ́ kí ó múra sílẹ̀, àní ìmúra gidigidi.”
8 Nikaikaihe’e hoe liona: O talè, Mitolom-pijagarodoñe am-pitala­kesañ’ abo atoy iraho te handro, le mijohañe am-pijilovako ey te haleñe.
Òun sì kígbe pé, kìnnìún kan, “Láti ọjọ́ dé ọjọ́, olúwa mi, mo dúró lórí ilé ìṣọ́ ní ọ̀sán, a sì fi mí ìṣọ́ mi ní gbogbo òru.
9 Heheke ondaty lia-raikeo, mpiningi-tsoavala kiroe-roe. Manoiñe ka re manao ty hoe: Rotsake, Rotsake t’i Bavele; fonga nivolentsa an-tane eo o saren-drahare’eo.
Wò ó, ọkùnrin kan ni ó ń bọ̀ wá yìí nínú kẹ̀kẹ́ ogun àti àkójọpọ̀ àwọn ẹṣin. Ó sì mú ìdáhùn padà wá: ‘Babeli ti ṣubú, ó ti ṣubú! Gbogbo àwọn ère òrìṣà rẹ̀ ló fọ́nká sórí ilẹ̀!’”
10 O ry linisakoo, ry anako an-toem-pamofohakoo, Hampahafohineko anahareo o raha tsinanoko am’ Iehovà’ i maroio, i Andrianañahare’ Israeley.
Ẹ̀yin ènìyàn mi, tí a gún mọ́lẹ̀ ní ilẹ̀ ìpakà, mo sọ ohun tí mo ti gbọ́ láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun, láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run Israẹli.
11 Ty nibangoeñe i Domà: Mikoike amako ty boak’e Seire: O mpigaritseo, manao akore i haleñey? O mpijiloo, akore ty haleñe toy?
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Dumahi. Ẹnìkan ké sí mi láti Seiri wá, “Alóre, kí ló kù nínú òru náà?”
12 Hoe i mpigaritsey: Hiporea’ ty maraindray, fa ho avy ka ty haleñe— ihe hañontane le mañontanea; mibaliha indraike!
Alóre náà dáhùn wí pé, “Òwúrọ̀ súnmọ́ tòsí, àti òru náà pẹ̀lú. Bí ìwọ yóò bá béèrè, béèrè; kí o sì tún padà wá.”
13 Ty entañe ho amy Arabe: Amo rongo-matahe’ i Arabeo ty hitobea’ areo ry mpivorontsa’ i Dedaneo.
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀ tí ó kan Arabia. Ẹ̀yin ẹgbẹ́ èrò ti Dedani, tí ó pàgọ́ sínú igbó Arabia,
14 Ry mpimone’ i Temao, anjotsò rano i taliñiereñey; Salakao ama’ ­mahakama o nivoratsakeo.
gbé omi wá fún àwọn tí òǹgbẹ ń gbẹ; ẹ̀yin tí ó ń gbé Tema, gbé oúnjẹ wá fún àwọn ìsáǹsá.
15 Ie nilaisa’ iareo o fibarao, i mesolava napotsoañey, naho i fale nibitsokey, vaho ty fanindria’ i aliy.
Wọ́n sá kúrò lọ́wọ́ idà, kúrò lọ́wọ́ idà tí a fàyọ, kúrò lọ́wọ́ ọrun tí a fàyọ àti kúrò nínú ìgbóná ogun.
16 Fa zao ty nafè’ i Talè amako: Añate ty taoñe raike, ami’ty fañiaham-pikarama, le ho hene modo ty enge’ i Kedare.
Èyí ni ohun tí Olúwa sọ fún mi: “Láàrín ọdún kan, gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀fà tí ó wà lábẹ́ ọgbà, í ti í kà á, gbogbo ògo ìlú Kedari yóò wá sí òpin.
17 Le tsy ho ampeampe ty sengaha’ o mpitàm-paleo, o lahilahy manjofake amo ana-Kedareoo; fa izay ty nitsara’ Iehovà, Andrianañahare’ Israele.
Àwọn tafàtafà tí ó sálà, àwọn jagunjagun ìlú Kedari kò ní tó nǹkan.” Olúwa, Ọlọ́run Israẹli ni ó ti sọ̀rọ̀.

< Isaia 21 >