< Hosea 2 >

1 Anò amo roahalahi’ areoo ty hoe: Amý, naho aman-droahavave’ areo ty hoe; Rohamà
“Sọ fún àwọn arákùnrin rẹ, ‘Ènìyàn mi,’ kí o sì wí fún àwọn arábìnrin rẹ ‘Àyànfẹ́ mi.’
2 Mifanjomora aman-drene’ areo; mifangatora; fa tsy tañanjombako, vaho tsy vali’e iraho. Aa le ampañafaho an-tarehe’e eo o hakarapiloa’eo naho añivo’ o fatroa’eo o hatsirimira’eo;
“Ẹ bá ìyá yín wí, ẹ bá a wí, nítorí pé kì í ṣe ìyàwó mi, Èmi náà kì í sì í ṣe ọkọ rẹ̀. Jẹ́ kí ó yọ àgbèrè rẹ̀ kúrò lójú rẹ̀ àti àìṣòótọ́ kúrò ní àyà rẹ̀.
3 tsy mone ho holireko, naho hapoko manahake i andro nahatoly azey, naho hanoeko hoe tane ratraratra, naho hadoko an-tane maik’ añe vaho havetrako an-karan-dranoañe.
Àìṣe bẹ́ẹ̀ èmi yóò tú u sí ìhòhò, Èmi yóò sì gbé e kalẹ̀ bí ọjọ́ tí a bí i. Èmi yóò ṣe ọ́ bí i aṣálẹ̀ ilẹ̀, Èmi yóò sì sọ ọ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀ Èmi yóò sì fi òǹgbẹ gbẹ ẹ́.
4 Tsy hiferenaiñako ka o ana’eo fa anak’amontoñe.
Èmi kò ní fi àánú mi hàn sí àwọn ọmọ rẹ̀ nítorí ọmọ àgbèrè ni wọ́n jẹ́.
5 Toe nanao satan-tsimirira ty rene’iareo nimeñatse i nampiareñe iareoy; ie nanao ty hoe, ho paiako añe o sakezako mamahañe ahy mofo naho rano, ty volon’añondry naho ty leniko, ty menake vaho ty finomakoo.
Nítorí ìyá wọn ti hùwà àgbèrè, ó sì lóyún wọn nínú ìtìjú. Ó wí pé, ‘Èmi ó tún tọ́ àwọn àyànfẹ́ mi lẹ́yìn, tó ń fún mi ní oúnjẹ àti omi, ní irun àgùntàn mi àti ọ̀gbọ̀ mi, òróró mi àti ohun mímu mi.’
6 Aa le ingo, ho faherako fatike ty lala’o, vaho hañoreñako kijoly tsy hahatreava’e ty homba’e.
Nítorí náà, èmi ó fi ẹ̀gún dì í lọ́nà, Èmi ó mọ odi yí i ká kí ó má ba à rọ́nà lọ.
7 Himanea’e orik’ amy zao o sakeza’eo fe tsy ho tra’e; ho paia’e iereo fa tsy ho trea’e; hanao ty hoe amy zao re, Homb’eo iraho himpoly mb’amy valiko valoha’ey mb’eo, fa nisoa te amo henaneo i henane zay.
Yóò sáré lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ṣùgbọ́n kò ní bá wọn; yóò wá wọn ṣùgbọ́n kò ní rí wọn. Nígbà náà ni yóò sọ pé, ‘Èmi ó padà sí ọ̀dọ̀ ọkọ mi àkọ́kọ́ nítorí pé ó dára fún mi nígbà náà ju ìsinsin yìí lọ.’
8 Fa namoea’e te nanjotsoako ampemba naho divay vaho menake; le nampitomboeko ama’e ty volafoty naho volamena nañamboare’ iareo Baaleo.
Nítorí pé kò tí ì mọ̀ pé èmi ni àti ẹni tó fún un ní ọkà, ọtí wáìnì tuntun àti òróró ẹni tí ó fún un ní fàdákà àti wúrà lọ́pọ̀lọ́pọ̀, èyí tí wọ́n lò fún Baali.
9 Hibalike iraho le hendeseko ty ampembako añ’andro’e naho ty divaiko an-tsa’e, vaho hasintako i volon’añondrikoy naho i leny natoloko aze hanaroña’e ty fihaloa’ey.
“Nítorí náà, èmi yóò mú ọkà mi kúrò nígbà tó bá pọ́n, èmi yóò sì mú wáìnì mi kúrò ní àsìkò rẹ̀. Èmi yóò sì gba irun àgùntàn àti ọ̀gbọ̀ mi padà ti mo ti fi fún un láti bo ìhòhò rẹ̀.
10 Ie henane zao, le ho boraheko ty fimeñara’e am-pahaisaha’ o sakeza’eo, le tsy eo ty hahavo­tsots’ aze an-tañako.
Èmi yóò sì fi ìwà ìtìjú rẹ̀ hàn lójú àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kò sí ẹni tí yóò gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ mi,
11 Fonga hajiheko o hafalefalea’eo, o sabadidam-pitontona’eo, naho o pea-bola’eo, naho o fitofa’eo vaho o hene androm-pamantaña’eo.
Èmi yóò mú gbogbo ayọ̀ rẹ̀ wá sí òpin: àjọ̀dún ọdọọdún rẹ̀, oṣù tuntun rẹ̀, ọjọ́ ìsinmi, àti gbogbo àwọn àjọ̀dún tí a yàn.
12 Ho firaeko añe o vahe’eo naho o sakoa’eo; i natao’e ty hoey, Tàngeko ‘nio, natolo’ o sakezakoo ahiko; aa le hafotsako ho ratraratra izay ho fihina’ o bibin-kivokeo.
Èmi yóò pa àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ run, èyí tí ó pè ní èrè rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, Èmi yóò sọ wọ́n di igbó, àwọn ẹranko búburú yóò sì jẹ́ wọn run.
13 Hampitiliheko ama’e ty andro’ o Baaleo, i nañoroa’e tsotse rezay, ie niravake o bange’eo naho o fomela’eo, naho nitsoeke o sakeza’eo vaho nandikok’ ahy, hoe t’Iehovà.
Èmi yóò bẹ̀ ọjọ́ Baalimu wò ní ara rẹ̀ nínú èyí tó ń fi tùràrí jóná fún Baali; tí ó fi òrùka etí àti ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀ọ́, tó sì tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ. Ṣùgbọ́n èmi ni òun gbàgbé,” ni Olúwa wí.
14 Aa le ingo t’ie ho sigiheko, naho hendeseko mb’am-patrambey mb’eo vaho hidiby aze an-troke.
“Nítorí náà, èmi yóò tàn án, Èmi ó sì mú u lọ sí ilẹ̀ aṣálẹ̀, Èmi ó fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ bá a sọ̀rọ̀
15 Le hatoloko aze ty tanem-bahe boak’añe, naho ty vavatane’ i Akore ho lalam-pampitamàñe; ie hisabo añe manahake tañ’andron-katora’e, hambañe amy andro niakara’e an-tane Mitsraime añey.
Níbẹ̀ ni èmi yóò ti dá ọgbà àjàrà rẹ̀ padà fún un, Èmi yóò fi àfonífojì Akori ṣe ìlẹ̀kùn ìrètí fún un. Yóò sì kọrin níbẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà èwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà tó kúrò ní Ejibiti.
16 Amy andro zay, hoe t’Iehovà, le ho kanjie’o iraho ami’ty hoe Valiko, vaho tsy hatao’o Baale ka.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò pè mí ní ‘ọkọ mi’; ìwọ kò sì ní pè mí ní ‘olúwa à mi mọ́,’ ni Olúwa wí.
17 Fa hasintako am-bava’e ao ty añara’ o Baaleo, vaho tsy ho toñoneñe ka o añara’eo.
Èmi yóò mú orúkọ, àwọn òrìṣà Baali kúrò lẹ́nu rẹ̀; ìwọ kò sì ní rí orúkọ òrìṣà Baali pè mọ́.
18 Ie amy andro zay, hanoeko fañina añivo’ iereo naho o bibin-kivokeo naho o voron-dikerañeo, naho o milaly an-tane eoo; le ho pozaheko ty fale naho ty fibara naho ty fihotakotaha’ ty tane toy vaho hampiroteko am-pierañerañañe.
Ní ọjọ́ náà, èmi yóò ṣe májẹ̀mú fún wọn àti àwọn ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti àwọn ẹ̀dá tí ń rìn lórí ilẹ̀. Kí wọn má bà á bẹ̀rù ara wọn mọ́. Ọfà, idà àti ogun jíjà ni èmi ó parun ní ilẹ̀ náà kí gbogbo ènìyàn bá a lè wà ní àìléwu.
19 Le ho fofoeko ho ahy nainai’e; eka ho fofoeko ho ahy an-kavantañañe naho an-katò naho an-kafatra­ram-pikokoañe naho fiferenaiñañe;
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi títí láé; Èmi ó fẹ́ ọ ní ìwà òdodo àti òtítọ́, ní ìfẹ́ àti àánú.
20 ie fofoeko ho ahy am-pigahiñañe, le ho fohi’o t’Iehovà.
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi ní òtítọ́ ìwọ yóò sì mọ Olúwa.
21 Ie amy andro zay, hoe t’Iehovà, le hamale iraho, ho toiñeko o likerañeo, vaho ho valè’ iereo i taney;
“Èmi yóò sì dáhùn ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí; “Èmi yóò dá àwọn ọ̀run lóhùn àwọn ọ̀run yóò sì dá ilẹ̀ lóhùn;
22 le hamale i ampembay naho i divaiy naho i menakey ty tane; vaho ho valè’ iareo t’Iezreèle.
ilẹ̀ náà yóò sì dá ọkà, wáìnì tuntun àti òróró lóhùn Gbogbo wọn ó sì dá Jesreeli lóhùn.
23 Le ho tongiseko ho ahy an-tane ao re; naho ho ferenaiñako i tsy niferenaiñañey naho hataoko amo tsy ni-ondatikoo ty hoe: Ondatiko irehe; vaho hanoa’ iareo ty hoe: Andrianañahareko.
Èmi ó sì gbìn ín fún ara mi lórí ilẹ̀ náà, Èmi yóò ṣàánú fún ẹni tí kò tì í ri ‘Àánú gbà.’ Èmi yóò sọ fún àwọn tí ‘Kì í ṣe ènìyàn mi pé,’ ‘Ẹ̀yin ni ènìyàn mi’; àwọn náà yóò sì wí pé, ‘Ìwọ ni Ọlọ́run mi.’”

< Hosea 2 >