< Asan'ny Apostoly 20 >

1 Aa naho nijihetse i koràkey, le nampihitrife’ i Paoly mb’ ama’e o mpiòkeo naho nifetrehe’e vaho nionjoñe mb’e Makedonia añe.
Nígbà tí ariwo náà sí rọlẹ̀, Paulu ránṣẹ́ pe àwọn ọmọ-ẹ̀yìn, ó sì gbà wọ́n ní ìyànjú, ó dágbére fún wọn, ó dìde láti lọ sí Makedonia.
2 Nirangae’e o taneo, nañosike ondatio an-tsara maro vaho nandoake e Grisia añe,
Nígbà tí ó sì tí la apá ìhà wọ̀nyí kọjá, tí ó sì ti fi ọ̀rọ̀ púpọ̀ gbà wọ́n ní ìyànjú, ó wá sí ilẹ̀ Giriki.
3 Nañialo telo volañe añe re. Aa naho nivoñoñ’ aze o Tehodao ie ho nijon-dakañe mb’e Sirià mb’eo, le sinafiri’e ty hibalik’ am-pirangañe i Makedonia.
Ó sì dúró níbẹ̀ ní oṣù mẹ́ta, nígbà tí àwọn Júù sì dènà dè é, bí ó ti ń pète àti bá ọkọ̀ ojú omi lọ sí Siria, ó pinnu rẹ̀ láti gbà Makedonia padà lọ.
4 Nindre ama’e t’i Sopatera ana’ i Pìro nte Berea naho i Aristarko naho i Sekondo nte Tesalonika naho i Gaio nte Derbe, le i Timoty naho i Tikìko vaho i Trofimo nte-Asia.
Sopateru ará Berea ọmọ Pirusi sì bá a lọ dé Asia, àti nínú àwọn ará Tẹsalonika, Aristarku àti Sekundu, àti Gaiusi ará Dabe, àti Timotiu; Tikiku àti Tirofimu ará Asia.
5 Niaolo anay iereo vaho nandiñe e Troasy ao.
Ṣùgbọ́n àwọn wọ̀nyí tí lọ síwájú, wọ́n dúró dè wá ni Troasi.
6 Aa naho niheneke o andro-Mofo-po-dalivaio le nijon-dakañe boak’e Filipy zahay; ie nimodo ty andro lime le nifanampe am’iereo e Troasy ao vaho nitambats’ ao fito andro.
Àwa sì ṣíkọ̀ láti Filipi lọ lẹ́yìn àjọ àìwúkàrà, a sì dé ọ̀dọ̀ wọn ní Troasi ni ọjọ́ méje.
7 Ie tsofotse ty andro’ i Sabotsey, ie fa nivory hamolake mofo o mpiòkeo, le nitaroñe am’iereo t’i Paoly, fa satri’e ty hiavotse amy loak’ àndroy, aa le nitolom-pilañoñe ampara’ te antets’ aleñe re.
Ọjọ́ èkínní ọ̀sẹ̀ nígbà tí àwọn ọmọ-ẹ̀yìn péjọ láti bu àkàrà, Paulu sì wàásù fún wọn, ó múra láti lọ ní ọjọ́ kejì: ó sì fa ọ̀rọ̀ rẹ̀ gùn títí di àárín ọ̀gànjọ́.
8 Nimaro ty jiro am-batsa nivoria’ay ao,
Fìtílà púpọ̀ sì wà ní iyàrá òkè náà, níbi tí wọn gbé péjọ sí.
9 le nitobok’ an-dalan-kede eo ty ajalahy atao Eotika naho nikonkoñe, aa ie tinohitohi’ i Paoly i lañona’ey, le nilañake ty roro i ajalahiy naho nikapotrake intelo riha mb’an-tane mb’eo vaho fola-manta te nongaheñe.
Ọ̀dọ́mọkùnrin kan tí a ń pè ní Eutiku sì jókòó lójú fèrèsé, oorun sì wọ̀ ọ́ lára; bí Paulu sì ti pẹ́ ní ìwàásù, ó ta gbọ̀nọ́ngbọ̀nọ́n lójú oorun, ó ṣubú láti òkè kẹta wá sílẹ̀, a sì gbé e dìde ní òkú.
10 Nizotso mb’eo t’i Paoly nihohok’ amy ajalahiy, ie nifihine’e, le hoe re, Ko hembañe, fa ama’e ty fiai’e!
Nígbà tí Paulu sì sọ̀kalẹ̀, ó bẹ̀rẹ̀ tì i, ó sì gbé e mọ́ra, ó ní, “Ẹ má ṣe yọ ara yín lẹ́nu; nítorí tí òun wà láààyè.”
11 Niañambone indraike t’i Paoly namolake mofo naho nikama, le nitolom-pitaroñe ampara’ te niporea ty maraindray vaho nienga.
Nígbà tí ó sì tún gòkè lọ, ó sì jẹ oúnjẹ Olúwa, ó sì sọ̀rọ̀ pẹ́ títí ó fi di àfẹ̀mọ́júmọ́, nígbà náà ni ó sì lọ.
12 Nindese’ iareo veloñe, am-panintsiñañe, i ajalahiy.
Wọ́n sì mú ọmọkùnrin náà lọ sílẹ̀ láààyè, inú gbogbo wọn sì dùn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
13 Fa niaolo aze an-dakan-jahay, nionjoñe mb’e Aso mb’eo, hampijoñe i Paoly añe amy namotoaña’ey, ie nañavelo am-pandia.
Nígbà ti àwa sì ṣáájú, àwa sì ṣíkọ̀ lọ sì Asosi, níbẹ̀ ni a ti lérò láti gba Paulu sínú ọkọ̀: nítorí bẹ́ẹ̀ ni ó tí pinnu rẹ̀, òun tìkára rẹ̀ ń fẹ́ bá ti ọ̀nà-ẹsẹ̀ lọ.
14 Aa ie nifanampe ama’ay e Aso ao, le najo’ay vaho nitolom-b’e Mitilena mb’eo.
Nígbà tí ó sì pàdé wa ní Asosi, a gbà á sínú ọkọ̀, a sì wá sí Miletu.
15 Nionjoñe boak’ao zahay le niporopotìtse tandrife’ i Kio te loak’ àndro. Amy hamarai’ey ka le nivotrake e Samo, vaho nandoake e Mileto añe amy loak’ àndroy.
Nígbà tí a sì ṣíkọ̀ kúrò níbẹ̀, ní ọjọ́ kejì a dé ọ̀kánkán Kiosi; ní ọjọ́ kejì rẹ̀ a dé Samosi, ni ọjọ́ kejì rẹ̀ a sì dé Miletu.
16 Sinafiri’ i Paoly ty handrioñe i Efesosy tsy handrìta’e andro maro e Asia ao, fa sinda te hañambeñe ty andro’ i Halimampoloy e Ierosaleme ao.
Paulu ṣa ti pinnu rẹ̀ láti bá ọkọ̀ ojú omi kọjá sí Efesu, nítorí ki ó má ba à lo àkókò kankan ni Asia: nítorí tí ó ń yára bí yóò ṣe ṣe é ṣe fún un láti wà ní Jerusalẹmu lọ́jọ́ Pentikosti.
17 Nampihitrike Efesosy añe boak’e Mileto re, nikoike o beim-Pivorio.
Ní àti Miletu ni Paulu ti ránṣẹ́ sí Efesu, láti pé àwọn alàgbà ìjọ wá sọ́dọ̀ rẹ̀.
18 Ie nitotsak’ ama’e, le hoe re: Fohi’ areo, boak’amy andro valoha’e nivotrahako Asia atoiy, ty fivelomako ama’ areo ze hene sà nitraofan-tika rezay,
Nígbà tí wọ́n sì dé ọ̀dọ̀ rẹ̀, ó wí fún wọn pé, “Ẹ̀yin tìkára yín mọ̀, láti ọjọ́ kìn-ín-ní tí mo tí dé Asia, bí mo ti bá yín gbé, ní gbogbo àkókò náà.
19 nitoroñe i Talè am-pirèhan-troke naho ranomaso maro ndra te teo ty fitsohañe ahy amo fikinià’ o Tehodaoo;
Bí mo ti ń fi ìrẹ̀lẹ̀ inú gbogbo sin Olúwa, àti omijé púpọ̀, pẹ̀lú ìdánwò, tí ó bá mi, nípa rìkíṣí àwọn Júù.
20 tsy nitsikifotse tsy hitaroñako ze mete mañasoa, fe nanoro anahareo an-tameañe vaho ki-anjomba-anjomba.
Bí èmí kò ti fàsẹ́yìn láti sọ ohunkóhun tí ó ṣàǹfààní fún un yín, àti láti máa kọ́ ọ yín ní gbangba àti láti ilé dé ilé.
21 Nafèko amo Jiosio naho amo Grikao ty fisolohoañe aman’Añahare naho ty fatokisañe Iesoà Talèntika Norizañey.
Tí mo ń sọ fún àwọn Júù, àti fún àwọn Giriki pẹ̀lú, ní ti ìrònúpìwàdà sí Ọlọ́run, àti ti ìgbàgbọ́ nínú Jesu Kristi Olúwa wa.
22 Ie henanekeo, oniño te mionjoñe mb’e Ierosaleme mb’eo an-troke mirohy le nofiko o raha mete hizò ahy añe;
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, ẹ̀mí mi ń fà sì Jerusalẹmu, láìmọ̀ ohun tí yóò bá mi níbẹ̀.
23 naho tsy te mañatahata ahy amy ze rova iaby i Arofo Masiñey t’ie mandiñe rohy naho sarerake.
Bí kò ṣe bí Ẹ̀mí Mímọ́ tí ń sọ ní ìlú gbogbo pé, ìdè àti ìyà ń bẹ fún mi.
24 Fe tsy volilieko ho vara amako ty fiaiko, hañenefako an-drebeke ty filaisako naho i fitoroñañe rinambeko am’ Iesoà Talèy, t'ie mitaroñe i talili-soa’ o falalàn’ Añahareoy.
Ṣùgbọ́n èmi kò ka ọkàn mi sí nǹkan rárá bi ohun tí ó ṣọ̀wọ́n fún mi àti iṣẹ́ ìránṣẹ́ tí mo tí gbà lọ́dọ̀ Jesu Olúwa, láti máa ròyìn ìyìnrere oore-ọ̀fẹ́ Ọlọ́run.
25 Inao, apotako henane zao te tsy hahaisake ty tareheko ka nahareo nindre amako amy fitaroñako i fifeheañeiy.
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí, wò ó, èmi mọ̀ pé gbogbo yín, láàrín ẹni tí èmi tí ń wàásù ìjọba Ọlọ́run, kì yóò rí ojú mi mọ́.
26 Ataliliko ama’ areo androany, te malio tahin-draho amy ze hene lio’ ondaty,
Nítorí náà mo pè yín ṣe ẹlẹ́rìí lónìí yìí pé, ọrùn mi mọ́ kúrò nínú ẹ̀jẹ̀ ènìyàn gbogbo.
27 le tsy nifimpìñe tsy hitaroñe ama’ areo ze fonga famerean’ Añahare.
Nítorí tí èmi kò fàsẹ́yìn láti sọ gbogbo ìpinnu Ọlọ́run fún un yin.
28 Mitaoa, naho itaò o mpirai-lia’e iabio, o nampiandraze’ i Arofo Masiñeio, hamahana’ areo i Fivorin’ Añahare vinili’e amy lio’eiy.
Ẹ kíyèsára yin, àti sí gbogbo agbo tí Ẹ̀mí Mímọ́ fi yín ṣe alábojútó rẹ̀, láti máa tọ́jú ìjọ Ọlọ́run, tí ó tí fi ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ rà.
29 Apotako te izaho fa nienga, le hizilik’ ama’ areo ao o amboa romotseo vaho tsy hapo’e i lia-raikey.
Nítorí tí èmi mọ̀ pé, lẹ́yìn lílọ mi, ìkookò búburú yóò wọ àárín yín, yóò sì tú agbo ká.
30 Toe hiboak’ ama’ areo ty ‘ndaty hiongake naho hivolan-kamengohañe, hanintake ty mpiòke ho am’iereo.
Láàrín ẹ̀yin tìkára yín ni àwọn ènìyàn yóò sì dìde, tí wọn yóò máa sọ̀rọ̀-òdì, láti fa àwọn ọmọ-ẹ̀yìn sẹ́yìn wọn.
31 Aa le mitomira! naho mitiahia te nañeneke ty telo taoñe iraho tsy nitroatse namere anahareo haleñe naho handro an-dranomaso.
Nítorí náà ẹ máa ṣọ́ra, ki ẹ sì máa rántí pé, fún ọdún mẹ́ta, èmi kò dẹ́kun láti máa fi omijé kìlọ̀ fún olúkúlùkù ní ọ̀sán àti ní òru.
32 Aa ie henaneo, tolorako aman’ Añahare naho ami’ty Tsara’ i hasoa’ey, ie ty mahatomambao anahareo, hanolotse anjara lova amy ze hene ondaty navaheñe.
“Ǹjẹ́ nísinsin yìí, ará, mo fi yín lé Ọlọ́run lọ́wọ́ àti ọ̀rọ̀ oore-ọ̀fẹ́ rẹ̀, tí ó lè gbé yín dúró, tí ó sì lè fún yín ní ìní láàrín gbogbo àwọn tí a sọ di mímọ́.
33 Tsy eo ty nikirañako volafoty ndra volamena ndra sarimbo.
Èmí kò ṣe ojúkòkòrò fàdákà, tàbí wúrà, tàbí aṣọ ẹnikẹ́ni.
34 Toe fohi’ areo te nañeneke o nipaiakoo naho o nitraok’ amakoo o tañako retoa.
Ẹ̀yin tìkára yín sá à mọ̀ pé, ọwọ́ mi wọ̀nyí ni mo fi ṣiṣẹ́ láti fi pèsè fún àìní mi, àti tí àwọn tí ó wà pẹ̀lú mi.
35 Fa nitoroako amy ze he’e amy fifanehafañe zay, ty hañimbà’ areo o malemeo, ie mitiahy ty tsara’ i Talè Iesoà manao ty hoe: Haha ty manjotso ta ty mandrambe.
Nínú ohun gbogbo mo fi àpẹẹrẹ fún un yín pé, nípa ṣíṣe iṣẹ́ bẹ́ẹ̀, ó yẹ kí ẹ máa ran àwọn aláìlera lọ́wọ́, ki ẹ sì máa rántí ọ̀rọ̀ Jesu Olúwa, bí òun tìkára rẹ̀ tí wí pé, ‘Láti fún ni ní ìbùkún ju láti gbà lọ.’”
36 Ie niheneke i saontsi’ey, le nitongaleke vaho nitrao-pilolok’ am’iereo iaby.
Nígbà tí ó sì tí wí nǹkan wọ̀nyí, ó kúnlẹ̀, ó sì bá gbogbo wọn gbàdúrà.
37 Sindre nirovetse, namontititse ty fititia’e naho nañondrok’ aze.
Gbogbo wọn sì sọkún gidigidi, wọ́n sì rọ̀ mọ́ Paulu lọ́rùn, wọ́n sì fi ẹnu kò ó lẹ́nu.
38 Loho nampihontoke iareo i tsara nanoe’e te tsy ho isa’ iereo ka i lahara’eiy; le nase­se’ iereo mb’ an-dakañe mb’eo.
Inú wọn sì bàjẹ́ jùlọ fún ọ̀rọ̀ tí ó sọ pé, wọn kì yóò rí ojú òun mọ́, wọ́n sì sìn ín títí dé inú ọkọ̀.

< Asan'ny Apostoly 20 >