< Ezeekyeri 19 >

1 Kungubagira abalangira ba Isirayiri,
“Kọ orin ọ̀fọ̀ nítorí àwọn ọmọ-aládé Israẹli
2 oyogere nti, “‘Maama wo nga yali mpologoma nkazi, mu mpologoma! Yagalamiranga wakati mu mpologoma ento, n’erabirira abaana baayo.
wí pé: “‘Èwo nínú abo kìnnìún ni ìyá rẹ̀ ní àárín àwọn kìnnìún yòókù? Ó sùn ní àárín àwọn ọ̀dọ́ kìnnìún ó sì ń tọ́jú àwọn ọmọ rẹ̀.
3 N’ekuza emu ku baana baayo n’efuuka empologoma ey’amaanyi, n’eyiga okuyigga ebisolo, n’okulya abantu.
Ó sì tọ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ dàgbà, ó sì di kìnnìún tó ní agbára, ó kọ́ ọ láti ṣọdẹ, ó sì ń pa àwọn ènìyàn jẹ.
4 Amawanga gaawulira ebimufaako, n’akwatirwa mu kinnya kye yali asimye, ne bamusibamu amalobo ne bamuleeta mu nsi y’e Misiri.
Àwọn orílẹ̀-èdè gbọ́ nípa rẹ̀, wọ́n sì fi ẹ̀wọ̀n mú un nínú iho wọn. Wọn fi ẹ̀wọ̀n mu nu lọ sí ilẹ̀ Ejibiti.
5 “‘Awo bwe yalaba essuubi lye nga terituukiridde, ne bye yali alindirira nga biyise, n’eddira emu ku baana baayo ab’empologoma endala, n’egifuula empologoma ey’amaanyi.
“‘Nígbà tí abo kìnnìún yìí rí pé ìrètí rẹ̀ sì jásí asán, ó mú ọmọ rẹ̀ mìíràn ó sì tún tọ́ ọ dàgbà di kìnnìún tó ní agbára.
6 N’etambulatambula mu mpologoma, kubanga yali efuuse empologoma ey’amaanyi, era n’eyiga okuyigga ensolo, n’okulya abantu.
Ó sì ń rìn káàkiri láàrín àwọn kìnnìún nítorí pé ó ti lágbára, o kọ ọdẹ ṣíṣe, ó sì pa àwọn ènìyàn.
7 N’emenyaamenya ebifo byabwe eby’amaanyi, n’ezikiriza n’ebibuga byabwe; ensi n’abo bonna abaagibeerangamu, ne batya olw’okuwuluguma kwayo.
Ó sì wó odi wọn palẹ̀ ó sì sọ àwọn ìlú wọn di ahoro. Ilẹ̀ náà àti àwọn olùgbé ibẹ̀ sì wà ní ìpayà nítorí bíbú ramúramù rẹ̀.
8 Awo amawanga gonna ne gagirumba, okuva mu bitundu ebyali byetooloddewo, ne bayanjuluza ekitimba kyabwe, ne bagikwatira mu kinnya kyabwe.
Nígbà náà ni àwọn orílẹ̀-èdè dìde sí i, àwọn tó yìí ká láti ìgbèríko wá. Wọn dẹ àwọ̀n wọn fún un, wọn sì mú nínú ihò wọn.
9 Ne bakozesa amalobo okugisikayo, ne bagiteeka mu kayumba ak’ebyuma, ne bagitwala eri kabaka w’e Babulooni; n’eteekebwa mu kkomera, n’etaddayo kuwulikika nate ku nsozi za Isirayiri.
Wọn fi ìwọ̀ gbé e sínú àgò, wọn mú un lọ sí ọ̀dọ̀ ọba Babeli, wọn fi sínú ìhámọ́, a kò sì gbọ́ bíbú rẹ̀ mọ́ lórí òkè Israẹli.
10 “‘Maama wo yali ng’omuzabbibu mu nnimiro ogwasimbibwa okumpi n’amazzi; ne gubala ebibala ne bijjula amatabi, kubanga waaliwo amazzi mangi.
“‘Ìyá rẹ dàbí àjàrà nínú ọgbà àjàrà rẹ̀; tí á gbìn sí etí odò ó, kún fún èso, ó sì kún fún ẹ̀ka nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi.
11 Amatabi gaagwo gaali magumu, era nga gasaanira okukolebwamu omuggo gw’obwakabaka. Omuzabbibu ogwo gwali muwanvu ne guyitamu okusinga emiti emirala, ne gumanyibwa olw’obuwanvu bwagwo, n’olw’amatabi gaagwo amangi.
Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ lágbára tó láti fi ṣe ọ̀pá àṣẹ ìjòyè, ó ga sókè láàrín ewé rẹ̀, gíga rẹ̀ hàn jáde láàrín ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ka rẹ̀.
12 Naye gwasigulibwa n’ekiruyi ne gusuulibwa wansi; embuyaga ez’Ebuvanjuba ne zigukaza, ebibala byagwo ne biggwaako, n’amatabi gaakwo amagumu ne gakala, era ne gwokebwa omuliro.
Ṣùgbọ́n ó fà á tu ní ìrunú, á sì wọ́ ọ lulẹ̀, afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn sì gbé èso rẹ̀, ọ̀pá líle rẹ̀ ti ṣẹ́, ó sì rọ iná sì jó wọn run.
13 Kaakano gusimbiddwa mu ddungu, awakalu awatali mazzi.
Báyìí, a tún ún gbìn sínú aṣálẹ̀ ni ilẹ̀ gbígbẹ àti ilẹ̀ tó ń pòǹgbẹ omi.
14 Omuliro gwava ku limu ku matabi, ne gwokya amatabi gaagwo n’ebibala byagwo. Tewasigadde ttabi ggumu na limu ku gwo eriyinza okukolwamu omuggo ogw’obwakabaka.’ Kuno kukungubaga, era kukozesebwa ng’okukungubaga.”
Iná sì jáde láti ọ̀kan lára ẹ̀ka rẹ̀ ó sì pa ẹ̀ka àti èso rẹ̀ run, dé bi pé kò sí ẹ̀ka tó lágbára lórí rẹ̀ mọ́; èyí to ṣe fi ṣe ọ̀pá fún olórí mọ́.’ Èyí ni orin ọ̀fọ̀ a o sì máa lo bí orin ọ̀fọ̀.”

< Ezeekyeri 19 >