< Sog̒u 19 >

1 Un tanīs dienās ķēniņa nebija iekš Israēla. Un viens vīrs, Levits, piemita aiz Efraīma kalniem, tas sev ņēma lieku sievu no Jūda Bētlemes.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì Israẹli kò ní ọba. Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Lefi tí ń gbé ibi tí ó sá pamọ́ nínú àwọn agbègbè òkè Efraimu, mú àlè kan láti Bẹtilẹhẹmu ní Juda.
2 Bet viņa liekā sieva pie viņa būdama dzina maucību un nogāja no viņa sava tēva namā uz Bētlemi Judā, un tur sabija kādu laiku, četrus mēnešus.
Ṣùgbọ́n àlè rẹ̀ náà sì ṣe panṣágà sí i, òun fi sílẹ̀, ó sì padà lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Bẹtilẹhẹmu ti Juda, ó sì wà ní ibẹ̀ ní ìwọ̀n oṣù mẹ́rin,
3 Tad viņas vīrs cēlās un gāja viņai pakaļ, ka tas mīlīgi ar viņu runātu un viņu vestu atpakaļ, un viņa puisis bija viņam līdz un pāris ēzeļu; un viņa to ieveda sava tēva namā, un kad tās sievietes tēvs viņu redzēja, tad viņš līksmojās viņam pretī (iedams).
ọkọ rẹ̀ lọ sí ibẹ̀ láti rọ̀ ọ́ pé kí ó padà sí ọ̀dọ̀ òun. Nígbà tí ó ń lọ ó mú ìránṣẹ́ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì lọ́wọ́, obìnrin náà mú un wọ inú ilé baba rẹ̀ lọ, nígbà tí baba obìnrin náà rí i ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á.
4 Un viņa tēvocis, tās sievietes tēvs, viņu paturēja, ka tas trīs dienas pie viņa palika, un tie ēda un dzēra un palika tur par nakti.
Àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà rọ̀ ọ́, ó sì borí rẹ̀ láti dá a dúró fún ìgbà díẹ̀, òun sì dúró fún ọjọ́ mẹ́ta, ó ń jẹ, ó ń mu, ó sì ń sùn níbẹ̀.
5 Un ceturtā dienā tie steidzās agri un cēlās iet projām. Tad tās sievietes tēvs sacīja uz savu znotu: stiprini savu sirdi ar kādu maizes kumosu, un tad jūs varat iet.
Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n dìde ní òwúrọ̀ kùtùkùtù òun sì múra láti padà lọ, ṣùgbọ́n baba ọmọbìnrin náà wí fún àna rẹ̀ pé, “Fi ohun jíjẹ díẹ̀ gbé inú ró nígbà náà kí ìwọ máa lọ.”
6 Tad tie apsēdās un ēda abi kopā un dzēra, un tās sievietes tēvs sacīja uz to vīru: dari lūdzams tā un paliec par nakti, un lai tava sirds līksmojās.
Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jókòó láti jọ jẹun àti láti jọ mu. Lẹ́yìn èyí ni baba ọmọbìnrin wí pé, “Jọ̀wọ́ dúró ní alẹ́ yìí kí o sì gbádùn ara rẹ.”
7 Bet tas vīrs cēlās iet projām, un viņa tēvocis to ļoti turēja, ka tam bija jāgriežas atpakaļ un tur jāpaliek par nakti.
Nígbà tí ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, baba ìyàwó rẹ̀ rọ̀ ọ́, torí náà ó sùn níbẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà.
8 Kad nu viņš piektā dienā no rīta taisījās aiziet, tad tās sievietes tēvs sacīja: stiprini jel savu sirdi; un tie kavējās, līdz kamēr vakars metās, un tie abi ēda kopā.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ karùn-ún nígbà tí ó dìde láti lọ, baba ọmọbìnrin wí pé, “Fi oúnjẹ gbé ara ró. Dúró de ọ̀sán!” Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jọ jẹun.
9 Tad tas vīrs cēlās aiziet, viņš un viņa liekā sieva un viņa puisis. Bet viņa tēvocis, tās sievietes tēvs, uz viņu sacīja: redzi jel, šī diena jau līdz vakaram ir pavadīta, paliec jel par nakti; redzi, šī diena beidzās, paliec par nakti šeitan un lai tava sirds līksmojās, dodaties rīt agri uz savu ceļu un ej uz savu dzīvokli.
Nígbà tí ọkùnrin náà, pẹ̀lú àlè àti ìránṣẹ́ rẹ̀, dìde láti máa lọ, àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà ní, “Wò ó ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, dúró níbí, ọjọ́ ti lọ. Dúró kí o sì gbádùn ara rẹ. Ìwọ lè jí ní àárọ̀ kùtùkùtù ọ̀la kí ìwọ sì máa lọ ilé.”
10 Bet tas vīrs negribēja par nakti palikt, un cēlās un aizgāja un nāca pret Jebuzu, tā ir Jeruzāleme, viņš un tas pāris apkrautu ēzeļu un viņa liekā sieva ar viņu.
Ṣùgbọ́n nítorí pé òun kò fẹ́ dúró mọ́ níbẹ̀ ní òru náà ọkùnrin náà kúrò ó sì gba ọ̀nà Jebusi: ọ̀nà Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ méjèèjì tí ó fi dì í ní gàárì àti àlè rẹ̀.
11 Kad nu tie pie Jebuzas bija, tad jau bija pavakars, un tas puisis sacīja uz savu kungu: nāc lūdzams un ieiesim šinī Jebusiešu pilsētā un paliksim tur par nakti.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jebusi tí ilẹ̀ ti fẹ́ ṣú tan, ìránṣẹ́ náà sọ fún ọ̀gá rẹ̀ pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a dúró ní ìlú yìí tí í ṣe ti àwọn ará Jebusi kí a sì sùn níbẹ̀.”
12 Bet viņa kungs uz viņu sacīja: mēs negribam griezties uz svešu pilsētu, kas nav no Israēla bērniem, bet gribam noiet līdz Ģibejai.
Ọ̀gá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Rárá o, àwa kì yóò wọ ìlú àwọn àjèjì, àwọn tí olùgbé ibẹ̀ kì í ṣe ọmọ Israẹli, a yóò dé Gibeah.”
13 Tad viņš sacīja uz savu puisi: nāc, ka mēs uz vienu no šīm vietām tiekam, un Ģibejā vai Ramā par nakti paliekam.
Ó fi kún un pé, ẹ wá ẹ jẹ́ kí a gbìyànjú kí a dé Gibeah tàbí Rama kí a sùn ní ọ̀kan nínú wọn.
14 Tā tie gāja tālāk un staigāja, un saule tiem nogāja it klātu pie Ģibejas, kas pieder Benjaminam.
Wọ́n sì tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn, oòrùn wọ̀ bí wọ́n ti súnmọ́ Gibeah tí ṣe ti àwọn Benjamini.
15 Un tie griezās uz turieni, ka nāktu un Ģibejā paliktu par nakti. Kad viņš nu iegāja, tad viņš apsēdās kādā pilsētas ielā, jo tur nebija neviena, kas tiem savā namā gribēja dot naktsmājas vietu.
Wọ́n yípadà wọ́n lọ sí inú ìlú Gibeah láti wọ̀ síbẹ̀ ní òru náà, wọ́n lọ wọ́n sì jókòó níbi gbọ̀ngàn ìlú náà, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó gbà wọ́n sínú ilé rẹ̀ láti wọ̀ sí.
16 Un redzi, viens vecs vīrs nāca vakarā no sava darba no tīruma, un tas vīrs arīdzan bija no Efraīma kalniem, bet piemita Ģibejā; bet tās vietas ļaudis bija Benjaminieši.
Ní alẹ́ ọjọ́ náà ọkùnrin arúgbó kan láti àwọn òkè Efraimu, ṣùgbọ́n tí ń gbé ní Gibeah (ibẹ̀ ni àwọn ẹ̀yà Benjamini ń gbé) ń ti ibi iṣẹ́ rẹ̀ bọ̀ láti inú oko.
17 Kad tas vecais vīrs nu savas acis pacēla, tad viņš to ceļa vīru ieraudzīja pilsētas ielā un sacīja: uz kurieni tu ej? Un no kurienes tu nāc?
Nígbà tí ó wòkè ó rí arìnrìn-àjò náà ní gbọ̀ngàn ìlú náà, ọkùnrin arúgbó yìí bi í léèrè pé, “Níbo ni ò ń lọ? Níbo ni o ti ń bọ̀?”
18 Un tas uz viņu sacīja: mēs no Jūda Bētlemes ejam aiz Efraīma kalniem, no kurienes es arī esmu, un es biju nogājis uz Jūda Bētlemi un es eju uz Tā Kunga namu, un neviena nav, kas man mājas vietu dod savā namā.
Ọmọ Lefi náà dá a lóhùn pé, “Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni àwa ti ń bọ̀, àwa sì ń lọ sí agbègbè tí ó sá pamọ́ ní àwọn òkè Efraimu níbi ti mo ń gbé. Mo ti lọ sí Bẹtilẹhẹmu ti Juda, èmi sì ń lọ sí ilé Olúwa nísinsin yìí. Kò sí ẹni tí ó gbà mí sí ilé rẹ̀.
19 Un tomēr salmi un ēdamais mums priekš mūsu ēzeļiem ir, arī maize un vīns priekš manis un priekš tavas kalpones un priekš tā puiša, kas ir pie taviem kalpiem; mums nekādas lietas netrūkst.
Àwa ní koríko àti oúnjẹ tó tó fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa àti oúnjẹ àti wáìnì fún àwa ìránṣẹ́ rẹ—èmi, ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú wa. A ò ṣe aláìní ohun kankan.”
20 Tad tas vecais vīrs sacīja: esi ar mieru, viss, kas tev trūkst, ir pie manis, tikai nepaliec par nakti uz ielas.
Ọkùnrin arúgbó náà sì wí pé. “Àlàáfíà fún ọ, bí ó ti wù kí ó rí, èmi yóò pèsè gbogbo ohun tí o nílò, kìkì pé kí ìwọ má ṣe sun ní ìgboro.”
21 Un viņš to veda savā namā un deva priekš tiem ēzeļiem ēdamo. Kad tie nu savas kājas bija mazgājuši, tad tie ēda un dzēra.
Òun sì mú wa sí ilé rẹ̀, ó ń bọ́ àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti wẹ ẹsẹ̀ wọn, àwọn àlejò náà jẹ, wọ́n mu.
22 Kad tie nu savu sirdi atspirdzināja, redzi, tad tās pilsētas vīri, bezdievīgi ļaudis, apstāja to namu un klaudzināja pie durvīm. Un tie sacīja uz to veco vīru, tā nama saimnieku: izved to vīru, kas nācis tavā namā, ka mēs to atzīstam.
Ǹjẹ́ bí wọ́n ti ń ṣe àríyá, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin ìlú náà, àwọn ọmọ Beliali kan, yí ilé náà ká, wọ́n sì ń lu ìlẹ̀kùn; wọ́n sì sọ fún baálé ilé náà ọkùnrin arúgbó náà pé, “Mú ọkùnrin tí ó wọ̀ sínú ilé rẹ wá, kí àwa lè mọ̀ ọ́n.”
23 Un tas vīrs, tā nama saimnieks, pie tiem izgāja un uz tiem sacīja: ne tā, mani brāļi, nedariet lūdzami tādu grēku; kad nu šis vīrs manā namā nācis, nedariet šo trakumu.
Ọkùnrin, baálé ilé náà sì jáde tọ̀ wọ́n lọ, ó sì wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin arákùnrin mi, èmi bẹ̀ yín, ẹ má ṣe hùwà búburú; nítorí tí ọkùnrin yìí ti wọ ilé mi, ẹ má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí.
24 Redzi, man ir viena meita, jaunava, un viņam lieka sieva, tās es jums gribu izvest, ka jūs tās piesmejat un tām darāt, kas jums patīk, bet pie šā vīra nedarāt tādu trakumu.
Kíyèsi i, ọmọbìnrin mi ni èyí, wúńdíá, àti àlè rẹ̀; àwọn ni èmi ó mú jáde wá nísinsin yìí, kí ẹ̀yin tẹ̀ wọ́n lógo, kí ẹ̀yin ṣe sí wọn bí ó ti tọ́ lójú yín: ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí ni kí ẹ̀yin má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí sí.”
25 Bet tie vīri to negribēja klausīt; tad tas vīrs sagrāba savu lieko sievu un to izveda pie viņiem ārā, un viņi to atzina un piesmēja cauru nakti līdz rītam un atlaida, kad gaisma metās.
Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà kò fetí sí tirẹ̀. Nítorí náà ọkùnrin náà mú àlè rẹ̀ ó sì tari rẹ̀ jáde sí wọn, wọ́n sì bá a fi ipá lòpọ̀, wọ́n sì fi gbogbo òru náà bá a lòpọ̀, nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́júmọ́ wọ́n jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́.
26 Un šī sieva nāca ap rīta laiku un krita pie zemes priekš tā vīra nama durvīm, kur viņas kungs iekšā bija, (un tur gulēja) līdz pat gaismai.
Nígbà tí ojúmọ́ bẹ̀rẹ̀ sí là obìnrin náà padà lọ sí ilé tí ọ̀gá rẹ̀ wà, ó ṣubú lulẹ̀ lọ́nà, ó sì wà níbẹ̀ títí ó fi di òwúrọ̀.
27 Kad nu viņas kungs rītā cēlās un nama durvis atdarīja un izgāja, savu ceļu staigāt, redzi, tad viņa liekā sieva gulēja priekš nama durvīm un viņas rokas uz sliekšņa.
Nígbà tí ọ̀gá rẹ̀ jí tí ó sì dìde ní òwúrọ̀ tí ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ilé náà, tí ó sì bọ́ sí òde láti tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò rẹ̀, kíyèsi i àlè rẹ̀ wà ní ṣíṣubú ní iwájú ilé, tí ọwọ́ rẹ̀ sì di òpó ẹnu-ọ̀nà ibẹ̀ mú,
28 Un viņš uz to sacīja: celies, ejam projām, bet tā neatbildēja. Tad tas vīrs to ņēma uz savu ēzeli un cēlās un gāja uz savām mājām.
òun sì wí fún obìnrin náà pé, “Dìde jẹ́ kí a máa bá ọ̀nà wa lọ.” Ṣùgbọ́n òun kò dá a lóhùn. Nígbà náà ni ọkùnrin náà gbé e lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì kọjá lọ sí ilé e rẹ̀.
29 Kad nu viņš savā namā nāca, tad viņš ņēma nazi un sagrāba savu lieko sievu un to sakapāja ar viņas kauliem divpadsmit daļās un to sūtīja uz visām Israēla robežām.
Nígbà tí ó dé ilé, ó mú ọ̀bẹ ó sì gé àlè rẹ̀ ní oríkeríke sí ọ̀nà méjìlá, ó sì fi wọ́n ránṣẹ́ sí gbogbo agbègbè Israẹli.
30 Un ikviens, kas to redzēja, tas sacīja: tāda lieta, kā šī, nav notikusi nedz redzēta, kamēr Israēla bērni no Ēģiptes zemes izgājuši līdz šai dienai. Tad nu jūs ņemiet to vērā, dodiet padomu un runājiet.
Gbogbo ẹni tí ó rí i sì wí pé, “A kò ti rí i, bẹ́ẹ̀ a kò tí ì ṣe irú nǹkan yìí rí, kì í ṣe láti ọjọ́ tí Israẹli ti jáde tí Ejibiti wá títí di òní olónìí. Ẹ rò ó wò, ẹ gbìmọ̀ràn, kí ẹ sọ fún wa ohun tí a yóò ṣe!”

< Sog̒u 19 >