< Ījaba 28 >
1 Tiešām, sudrabam ir savi ceļi, kur tas rodas, un kausējamam zeltam sava vieta.
Nítòótọ́, koto fàdákà ń bẹ, àti ibi tí wọ́n ti máa ń da wúrà.
2 Dzelzs no zemes top ņemta, un no akmeņiem varš top kausēts.
Nínú ilẹ̀ ni à ń gbé ń wa irin, bàbà ni a sì ń dà láti inú òkúta wá.
3 Tumsai gals likts, un caur caurim cilvēks izmeklē arī pašā galējā tumsā apslēptos akmeņus.
Ènìyàn ni ó fi òpin si òkùnkùn, ó sì ṣe àwárí ìṣúra láti inú òjìji ikú sí ìhà gbogbo.
4 Viņš izrok ceļu turp, kur neviens nedzīvo, un kur neviena kāja neved; tur viņš karājās un nolaižās tālu no cilvēkiem.
Wọ́n wa ihò ilẹ̀ tí ó jì sí àwọn tí ń gbé òkè, àwọn tí ẹsẹ̀ ènìyàn gbàgbé wọ́n rọ́ sí ìsàlẹ̀, wọ́n rọ́ sí ìsàlẹ̀ jìnnà sí àwọn ènìyàn.
5 No zemes virsas izaug maize, viņas apakša top apgriezta kā no uguns.
Bí ó ṣe ti ilẹ̀ ni, nínú rẹ̀ ni oúnjẹ ti ń jáde wá, àti ohun tí ó wà ní ìsàlẹ̀ ni ó yí padà bi iná;
6 Viņas akmeņos ir safīri, un tur rodas zelta graudi.
òkúta ibẹ̀ ni ibi òkúta safire, o sì ní erùpẹ̀ wúrà.
7 Ne ērglis šo ceļu nav ieraudzījis, ne vanaga acs to nav redzējusi.
Ipa ọ̀nà náà ni ẹyẹ kò mọ̀, àti ojú gúnnugún kò rí i rí.
8 Briesmīgi zvēri pa to nav gājuši, un lauva pa to nav staigājis.
Àwọn ẹranko agbéraga kò rìn ibẹ̀ rí, bẹ́ẹ̀ ni kìnnìún tí ń ké ramúramù kò kọjá níbẹ̀ rí.
9 Cilvēks pieliek savu roku pie akmeņiem, un izrok kalnu pamatus;
Ó fi ọwọ́ rẹ̀ lé akọ òkúta, ó yí òkè ńlá po láti ìdí rẹ̀ wá.
10 Viņš izcērt ceļus akmeņu kalnos, un viņa acs ierauga visādus dārgumus;
Ó sì la ipa odò ṣíṣàn nínú àpáta, ojú inú rẹ̀ sì rí ohun iyebíye gbogbo.
11 Viņš aizdara ūdeņus, kā nesūcās cauri, un izved gaismā, kas ir apslēpts.
Ó sì ṣe ìṣàn odò kí ó má ṣe kún àkúnya, ó sì mú ohun tí ó pamọ́ hàn jáde wá sí ìmọ́lẹ̀.
12 Bet gudrību, kur to atrod, un kur mājo atzīšana?
Ṣùgbọ́n níbo ni á ó gbé wá ọgbọ́n rí, níbo sì ni òye ń gbe?
13 Cilvēks nezin, ar ko lai to pērk un dzīvo zemē to nevar uziet.
Ènìyàn kò mọ iye rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni a kò le è rí i ní ilẹ̀ àwọn alààyè.
14 Bezdibenis saka: te viņas nav; un jūra saka: tā nav pie manis.
Ọ̀gbun wí pé, “Kò sí nínú mi”; omi òkun sì wí pé, “Kò si nínú mi.”
15 Zeltu par viņu nevar dot, nedz sudraba maksu par viņu iesvērt.
A kò le è fi wúrà rà á, bẹ́ẹ̀ ni a kò le è fi òsùwọ̀n wọn fàdákà ní iye rẹ̀.
16 To nevar uzsvērt ar Ofira zeltu nedz ar dārgiem oniksa un safīra akmeņiem.
A kò le è fi wúrà Ofiri, tàbí òkúta óníkìsì iyebíye, tàbí òkúta safire díye lé e.
17 To neatsver ne zelts, ne spīdoši akmeņi, to nevar izmīt pret zelta glītumiem.
Wúrà àti òkúta kristali kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni a kò le è fi ohun èlò wúrà ṣe pàṣípàrọ̀ rẹ̀.
18 Par pērlēm un kristālu nav ko runāt; jo gudrību mantot ir pārāki par pērlēm.
A kò lè dárúkọ iyùn tàbí òkúta jasperi; iye ọgbọ́n sì ju iyùn lọ.
19 Moru zemes topāzs viņai nav līdzīgs, un visu šķīstais zelts viņu nepanāk.
Òkúta topasi ti Kuṣi kò tó ẹgbẹ́ rẹ̀; bẹ́ẹ̀ ni a kò le fi wúrà dáradára díwọ̀n iye rẹ̀.
20 Nu tad, no kurienes nāk gudrība un kur mājo atzīšana?
Níbo ha ni ọgbọ́n ti jáde wá? Tàbí níbo ni òye ń gbé?
21 Jo tā ir apslēpta priekš visu acīm, kas dzīvo, un putniem apakš debess tā ir nezināma.
A rí i pé, ó fi ara sinko kúrò ní ojú àwọn alààyè gbogbo, ó sì fi ara sin fún ẹyẹ ojú ọ̀run.
22 Elle un nāve saka: ar savām ausīm gan esam dzirdējuši viņas slavu.
Ibi ìparun àti ikú wí pé, àwa ti fi etí wa gbúròó rẹ̀.
23 Dievs pazīst viņas ceļu, un Tas zin viņas vietu.
Ọlọ́run ni ó mọ òye ipa ọ̀nà rẹ̀, òun ni ó sì mọ ibi tí ó ń gbé.
24 Jo Viņš skatās līdz pasaules galiem, Viņš redz, kas apakš visām debesīm.
Nítorí pé ó wòye dé òpin ayé, ó sì rí gbogbo ìsàlẹ̀ ọ̀run,
25 Kad Viņš vējam deva savu svaru un ūdeni nosvēra pēc mēra,
láti dà òsùwọ̀n fún afẹ́fẹ́, ó sì fi òsùwọ̀n wọ́n omi.
26 Kad Viņš lietum sprieda likumu un zibenim un pērkonam ceļu,
Nígbà tí ó pàṣẹ fún òjò, tí ó sì la ọ̀nà fún mọ̀nàmọ́ná àrá,
27 Tad Viņš to izredzēja un to izteica, Viņš to sataisīja un izdibināja,
nígbà náà ni ó rí i, ó sì sọ ọ́ jáde; ó pèsè rẹ̀ sílẹ̀, ó sì ṣe ìwádìí rẹ̀ rí.
28 Un sacīja uz cilvēku: redzi, Tā Kunga bijāšana, tā ir gudrība, un atstāties no ļauna, tā ir atzīšana.
Àti fún ènìyàn ni ó wí pé, “Kíyèsi i, ẹ̀rù Olúwa èyí ni ọgbọ́n, àti láti jáde kúrò nínú ìwà búburú èyí ni òye.”