< Jeremiah 17 >

1 LEUM GOD El fahk, “Mwet Judah, ma koluk lowos simla ke pen osra soko. Kihlisyukyak insiowos ke mutun pin diamond soko, ac kihlyak ke sruwasrik in loang lowos.
“Ẹ̀ṣẹ̀ Juda ni a fi kálámù irin kọ, èyí tí a fi ṣóńṣó òkúta adamante gbẹ́ ẹ, sórí wàláà oókan àyà wọn, àti sórí ìwo pẹpẹ yín.
2 Mwet lowos uh alu ke loang uh ac ke lumah ma tulokyak nu sin god mutan Asherah, ye sak folfol nukewa ac fin tohktok uh,
Kódà àwọn ọmọ wọn rántí pẹpẹ àti ère Aṣerah lẹ́bàá igi tí ó tẹ́ rẹrẹ àti àwọn òkè gíga.
3 ac yen turangang fineol uh. Nga fah lela mwet lokoalok lowos in usla mwe kasrup ac ma saok lowos ke sripen ma koluk lowos nukewa ma kowos orala in acn suwos.
Àwọn òkè nínú ilẹ̀ àti àwọn ọrọ̀ rẹ̀ àti ọlá rẹ̀ ni èmi yóò fi sílẹ̀ bí ìjẹ pẹ̀lú àwọn ibi gíga, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí ó pọ̀ káàkiri orílẹ̀-èdè yín.
4 Kowos fah enenu in fuhleak facl se ma nga sot nu suwos, ac nga fah oru tuh kowos in orekma nu sin mwet lokoalok lowos in sie facl ma wangin etu lowos kac, mweyen kasrkusrak luk oana sie e ma ac firir nwe tok.”
Láti ipasẹ̀ àìṣedéédéé yín ni ẹ̀yin yóò ti sọ ogún tí mo fún un yín nù. Èmi yóò fi yín fún ọ̀tá yín bí ẹrú ní ilẹ̀ tí ẹ̀yin kò mọ̀, nítorí ẹ̀yin ti mú inú bí mi, èyí tí yóò sì wà títí ayé.”
5 LEUM GOD El fahk, “Nga fah selngawi mwet se Su forla likiyu Ac filiya lulalfongi lal sin mwet, Ac lulalfongi ku lun mwet sukawil moul la.
Báyìí ni Olúwa wí: “Ègbé ni fún àwọn tí ó fi ìgbẹ́kẹ̀lé wọn sínú ènìyàn, tí ó fi agbára rẹ̀ sínú ẹran-ara, àti tí ọkàn rẹ̀ kò sí lọ́dọ̀ Olúwa.
6 El oana soko mahsrik in acn mwesis Ma kapak in acn pao, yen wangin ma oan we, Fin acn kifintela, yen wangin pac ma ku in kapak we. Wangin ma wo ku in sonol.
Yóò dàbí igbó tí ó wà ní ilẹ̀ aláìlọ́ràá, kò ní rí ìre, nígbà tí ó bá dé, yóò máa gbé ní ibi ìyàngbẹ ilẹ̀ aginjù, ní ilẹ̀ iyọ̀ tí ẹnikẹ́ni kò gbé.
7 “Tusruktu nga ac fah akinsewowoye mwet se Su filiya lulalfongi lal in nga.
“Ṣùgbọ́n ìbùkún ni fún ọkùnrin náà tí ó gbẹ́kẹ̀lé Olúwa, tí ó sì fi Olúwa ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ̀.
8 El oana soko sak ma kap sisken soko infacl srisrik Ac kapla okahl nwe ke sun kof uh. Wangin sangeng lal ke pacl fol Mweyen sroan sak uh folfolna. El tia fosrnga finne wangin af. Pacl nukewa oasr fahko kacl.
Yóò dàbí igi tí a gbìn sí ipadò tí ó ta gbòǹgbò rẹ̀ ká etí odò kò sí ìbẹ̀rù fún un nígbà ooru, gbogbo ìgbà ni èwe rẹ̀ máa ń tutù kò sí ìjayà fún un ní ọdún ọ̀dá bẹ́ẹ̀ ni kò ní dẹ́kun láti máa so èso.”
9 “Su ku in etu ma oan insien mwet? Wangin ma kutasrik oana nunak lun mwet — Sie ma su tia ku in akkeyeyukla.
Ọkàn ènìyàn kún fún ẹ̀tàn ju ohun gbogbo lọ, ó kọjá ohun tí a lè wòsàn. Ta ni èyí lè yé?
10 Nga, LEUM GOD, iluhs nunak lun mwet, Ac srike insialos. Nga oru nu sin kais sie mwet fal nu ke ouiyen moul lal, Ac fal nu ke orekma lal.”
“Èmi Olúwa ń wo ọkàn àti èrò inú ọmọ ènìyàn, láti san èrè iṣẹ́ rẹ̀ fún un gẹ́gẹ́ bí ọ̀nà rẹ̀, àti gẹ́gẹ́ bí iṣẹ́ ọwọ́ rẹ̀.”
11 Mwet se su eis mani lal ke sesuwos El oana sie won ma sawulla atro ma tia ma natul. Ke mwet sac el sun kuiyal, na mwe kasrup lal ac wanginla, Ac saflaiyal el fah sie mwet lalfon.
Bí àparò tó pa ẹyin tí kò yé ni ọmọ ènìyàn tí ó kó ọrọ̀ jọ ni ọ̀nà àìṣòdodo. Yóò di ẹni ìkọ̀sílẹ̀ ní agbede-méjì ayé rẹ̀, àti ní òpin rẹ̀ yóò wá di aṣiwèrè.
12 Tempul sesr oana sie tron oaskulana, Musaiyukyak fin soko eol fulat ke mutawauk ah me.
Ìtẹ́ ògo; ibi gíga láti ìpilẹ̀ṣẹ̀ ní ibi ilé mímọ́ wa.
13 LEUM GOD, kom mwe finsrak lun Israel. Elos nukewa su siskomla ac fah akmwekinyeyuk. Elos ac fah wanginla oana inen mwet ma simla fin fohk uh, Mweyen elos siskomla, LEUM GOD, Su oana unon in kof se.
Olúwa ìwọ ni ìrètí Israẹli; gbogbo àwọn tí ó kọ̀ ọ́ sílẹ̀ ni ojú ó tì. Àwọn tí ó padà sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ rẹ ni a ó kọ orúkọ wọn sínú ekuru, nítorí wọ́n ti kọ Olúwa, orísun omi ìyè sílẹ̀.
14 LEUM GOD, akkeyeyula ac nga fah kwela na pwaye. Langoeyula ac nga fah moulla. Kom na pa nga kaksakin uh!
Wò mí sàn Olúwa, èmi yóò di ẹni ìwòsàn, gbà mí là, èmi yóò di ẹni ìgbàlà, nítorí ìwọ ni ìyìn mi.
15 Mwet uh fahk nu sik, “Pia ma LEUM GOD El fahk mu El ac oru nu sesr ah? Lela Elan orala ingena!”
Wọ́n sọ fún mi wí pé: “Níbo ni ọ̀rọ̀ Olúwa wà? Jẹ́ kí ó di ìmúṣẹ báyìí.” Ni Olúwa wí.
16 Tusruktu, LEUM GOD, nga tiana kwafe sum in kunauselosla. Nga tiana ke in oasr pacl se koluk nu selos. LEUM GOD, kom etu ma inge. Kom etu ma nga tuh fahk ah.
Èmi kò sá kúrò láti máa jẹ́ olùṣọ àgùntàn rẹ, ìwọ mọ̀ wí pé èmi kò kẹ̀rẹ̀ ní ọjọ́ ìpọ́njú. Ohun tí ó jáde ní ètè mi jẹ́ èyí tí ó hàn sí ọ.
17 Nimet kom oana sie mwe aksangeng nu sik. Kom pa nien molela luk ke pacl koluk sikyak.
Má ṣe di ìbẹ̀rù fún mi, ìwọ ni ààbò mi ní ọjọ́ ìpọ́njú.
18 LEUM GOD, akmwekinyalos su kalyeiyu, tusruktu nimet akmwekinyeyu. Nwakulosla ke mwe aksangeng, ac nikmet akfosrngayeyu. Akyokye mwe ongoiya nu faclos ac kunauselosla nu ke ip srisrik.
Jẹ́ kí ojú ti àwọn ẹni tí ń lépa mi, ṣùgbọ́n pa mí mọ́ kúrò nínú ìtìjú, jẹ́ kí wọn kí ó dààmú. Mú ọjọ́ ibi wá sórí wọn, fi ìparun ìlọ́po méjì pa wọ́n run.
19 LEUM GOD El fahk nu sik, “Jeremiah, fahla nu ke Mutunpot lun Mwet uh, yen ma tokosra lun Judah elos uti-utyak nu in siti uh, ac sulkakin kas luk inge we. Toko kom fah som nu ke mutunpot nukewa saya lun Jerusalem.
Èyí ni ohun tí Olúwa wí fún mi: “Lọ dúró ní ẹnu-ọ̀nà àwọn ènìyàn níbi tí àwọn ọba Juda ń gbà wọlé tí wọ́n ń gbà jáde àti ní gbogbo ẹnu-bodè Jerusalẹmu.
20 Fahk nu sin tokosra ac mwet Judah nukewa, ac elos nukewa su muta Jerusalem ac orekmakin mutunpot inge, in porongo ma nga fahk uh.
Sọ fún wọ́n pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọba Juda àti gbogbo ẹ̀yin ènìyàn Juda àti gbogbo ẹ̀yin tí ń gbé ní Jerusalẹmu tí ń wọlé láti ẹnu ibodè yìí.
21 Fahk nu selos lah elos fin seko moul lalos, elos in tia lippise kutena ma toasr ke len Sabbath. Elos in tia us kutena ma toasr utyak ke mutunpot lun Jerusalem,
Báyìí ni Olúwa wí, “Ẹ kíyèsi láti máa ru ẹrù lọ́jọ́ ìsinmi tàbí kí ẹ gbé wọlé láti ẹnu ibodè Jerusalẹmu.
22 ku us kutena ma toasr illa liki lohm selos ke len Sabbath. Elos in tiana orekma ke len Sabbath. Elos in akfulatye oana sie len mutal, oana ke nga tuh sapkin nu sin mwet matu lalos.
Má ṣe gbé ẹrù jáde kúrò nínú ilé yín, bẹ́ẹ̀ ni kí ẹ má ṣe ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ ìsinmi ṣùgbọ́n kí ẹ pa ọjọ́ ìsinmi mọ́ fún àwọn baba ńlá yín.”
23 Mwet matu lalos ah tuh tiana porongeyu ku akosyu. A ma elos oru pa elos likkekeiyu na ac tia lohma nu ke kas in luti luk.
Síbẹ̀ wọn kò gbọ́ tàbí tẹ́tí sílẹ̀, wọ́n jẹ́ ọlọ́rùn líle; wọn kì í fẹ́ gbọ́ tàbí gba ìbáwí.
24 “Fahk nu sin mwet inge lah elos enenu na in akos ma sap luk nukewa. Elos in tiana us kutena ma toasr fahsr ke mutunpot in siti se inge ke len Sabbath. Elos enenu in akmutalye len Sabbath ac tia oru kutena orekma.
Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kíyèsi láti gbọ́ tèmi ní Olúwa wí, tí ẹ kò sì gbe ẹrù gba ẹnu-bodè ìlú ní ọjọ́ ìsinmi, ṣùgbọ́n tí ẹ ya ọjọ́ ìsinmi, sí mímọ́, nípa pé ẹ kò ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ ní ọjọ́ náà.
25 Na tokosra lalos, ac fisrak lalos, fah ilyak ke mutunpot lun Jerusalem ac eis pacna ku fulat se ma tuh oan facl David. Elos fah wi na mwet Judah ac mwet Jerusalem kasrusr fin chariot ac fin horse, ac siti Jerusalem fah sessesla ke mwet pacl nukewa.
Nígbà náà ni ọba tí ó jókòó lórí ìtẹ́ Dafidi yóò gba ẹnu ibodè wọlé pẹ̀lú àwọn ìjòyè rẹ̀. Àwọn àti ìjòyè wọn yóò gun ẹṣin àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wá, àwọn ọkùnrin Juda àti àwọn olùgbé Jerusalẹmu yóò tẹ̀lé wọn; ìlú yìí yóò sì di ibi gbígbé títí láéláé.
26 Mwet uh ac fah tuku liki siti srisrik lun Judah ac liki inkul ma raunela Jerusalem. Elos fah tuku liki facl lun Benjamin, liki pe eol uh, fineol uh, ac liki layen eir in Judah. Elos fah us nu in Tempul sik mwe kisa firir, ac kisakin mwe kisa wheat ac mwe keng, oayapa mwe kisa in sang kulo.
Àwọn ènìyàn yóò wá láti ìlú Juda àti ní agbègbè Jerusalẹmu, láti ilẹ̀ Benjamini, láti pẹ̀tẹ́lẹ̀, àti láti òkè, àti láti gúúsù wá, wọn yóò wá pẹ̀lú ọrẹ ẹbọ sísun, àti ọrẹ ẹran, àti tùràrí, àti àwọn tó mú ìyìn wá sí ilé Olúwa.
27 Tusruktu elos enenu in akosyu ac karinganang len Sabbath tuh in sie len mutal. Elos in tia us kutena ma toasr fahsr ke mutunpot Jerusalem ke len sac, mweyen elos fin oru, nga ac esukak mutunpot Jerusalem. E uh ac fah furreak lohm sin tokosra Jerusalem, ac wangin mwet fah ku in konela.”
Ṣùgbọ́n bí ẹ̀yin kò bá pa òfin mi mọ́ láti ya ọjọ́ ìsinmi sí mímọ́, kí ẹ má sì ṣe ru ẹrùkẹ́rù bí ẹ̀yin yóò ṣe máa gba ẹnu ibodè Jerusalẹmu wọlé ní ọjọ́ ìsinmi, nígbà náà ni èmi yóò da iná tí kò ní ṣe é parun ní ẹnu-bodè Jerusalẹmu tí yóò sì jó odi agbára rẹ̀.’”

< Jeremiah 17 >