< Deuteronomy 32 >
1 “Faclu ac yen engyeng uh, lohng kas luk, Lohng akwoya ma nga ac fahk inge.
Fetísílẹ̀, ẹ̀yin ọ̀run, èmi yóò sọ̀rọ̀; ẹ gbọ́, ìwọ ayé, ọ̀rọ̀ ẹnu mi.
2 Mwe luti luk fah putat oana tulin af, Ac sikyak fin faclu oana aunfong. Kas luk fah putat oana af sringsring nu fin sacn ma tufahna srunak, Oana af loang nu fin mah srisrik uh.
Jẹ́ kí ẹ̀kọ́ ọ̀ mi máa rọ̀ bí òjò, kí àwọn ọ̀rọ̀ mi máa sọ̀kalẹ̀ bí ìrì, bí òjò wíníwíní sára ewéko tuntun, bí ọ̀wààrà òjò sára ohun ọ̀gbìn.
3 Nga fah kaksakin Inen LEUM GOD, Ac mwet lal fah fahkak fulatlana lal.
Èmi yóò kókìkí orúkọ Olúwa. Ẹyin títóbi Ọlọ́run wa!
4 “LEUM GOD El nien molela kulana lowos, El suwohs ac pwaye in ma nukewa El oru; God lowos El oaru ac pwaye; El suwoswos ac El oru ma suwohs.
Òun ni àpáta, iṣẹ́ ẹ rẹ̀ jẹ́ pípé, gbogbo ọ̀nà an rẹ̀ jẹ́ òdodo. Ọlọ́run olóòtítọ́ tí kò ṣe àṣìṣe kan, Ó dúró ṣinṣin, òdodo àti òtítọ́ ni òun.
5 A kowos tia pwaye nu sel; kowos tia fal in mwet lal, Sie mutanfahl koluk ac kutasrik.
Wọ́n ti ṣe iṣẹ́ ìbàjẹ́ sọ́dọ̀ ọ rẹ̀; fún ìtìjú u wọn, wọn kì í ṣe ọmọ rẹ̀ mọ́, ṣùgbọ́n ìran tí ó yí sí apá kan tí ó sì dorí kodò.
6 Kowos mwet lalfon ac selalkung, Ya kowos ac moli kulang lun LEUM GOD ouinge? El papa tomowos; El pa orekowosla, El oru tuh kowos in sie mutunfacl.
Ṣé báyìí ni ẹ̀yin yóò ṣe san an fún Olúwa, ẹ̀yin aṣiwèrè àti aláìgbọ́n ènìyàn? Ǹjẹ́ òun kọ́ ni baba yín, Ẹlẹ́dàá yín, tí ó dá a yín tí ó sì mọ yín?
7 “Nunku ke pacl meet ah, ke fwilin mwet somsomla; Siyuk papa tomowos in srumun nu suwos lah mea sikyak meet, Siyuk sin mwet matu in srumun ke pacl somla.
Rántí ìgbà láéláé; wádìí àwọn ìran tí ó ti kọjá. Béèrè lọ́wọ́ baba à rẹ yóò sì sọ fún ọ, àwọn àgbàgbà rẹ, wọn yóò sì ṣàlàyé fún ọ.
8 El su Fulatlana El oakiya acn nu sin kais sie mutunfacl; El kitalik acn, ac srisrngiya masrol nu ke acn in muta lun mwet uh. El sang lipufan in karingin kais sie mutunfacl.
Nígbà tí Ọ̀gá-ògo fi ogún àwọn orílẹ̀-èdè fún wọn, nígbà tí ó pín onírúurú ènìyàn, ó sì gbé ààlà kalẹ̀ fún àwọn ènìyàn gẹ́gẹ́ bí iye ọmọkùnrin Israẹli.
9 A El sulela fwilin tulik natul Jacob nu sel sifacna.
Nítorí ìpín Olúwa ni àwọn ènìyàn an rẹ̀, Jakọbu ni ìpín ìní i rẹ̀.
10 “El konalosyak ke elos raraun yen mwesis, Sie acn wangin mwet muta we, a pusren ngirngir na lun eng uh. El loangelosla ac karinganulosyang, Mweyen elos arulana saok sel.
Ní aginjù ni ó ti rí i, ní aginjù níbi tí ẹranko kò sí. Ó yíká, ó sì tọ́jú rẹ̀, ó pa á mọ́ bí ẹyin ojú u rẹ̀.
11 Oana ke sie eagle el luti ma fusr natul in sohksok ke el ac sinukla liki ang uh, Na el ukwalos in molelosla ac srakalosyak fin posohksok lal, Ouinge LEUM GOD El liyaung Israel tuh elan tia putatla.
Bí idì ti í ru ìtẹ́ rẹ̀ ti ó sì ń rábàbà sórí ọmọ rẹ̀, tí ó na ìyẹ́ apá rẹ̀ láti gbé wọn ki ó sì gbé wọn sórí ìyẹ́ apá rẹ̀.
12 LEUM GOD mukena kolma mwet lal, Ac wangin kasru sin god saya.
Olúwa ṣamọ̀nà; kò sì sí ọlọ́run àjèjì pẹ̀lú rẹ̀.
13 “El lela nu selos in leumi fulan eol uh, Ac elos kang ma kapak inimae. Elos konauk honey inmasrlon eot uh; Sak olive sunalos kapak wo in acn eoteot uh.
Ó mú gun ibi gíga ayé ó sì fi èso oko bọ́ ọ. Ó sì jẹ́ kí ó mú oyin láti inú àpáta wá, àti òróró láti inú akọ òkúta wá.
14 Cow ac nani natulos arulana sroanom tetelos; Un sheep ac nani ac cow natulos pa wo oemeet; Wheat ac wain lalos arulana yu.
Pẹ̀lú u wàràǹkàṣì àti wàrà àgùntàn àti ti àgbò ẹran àti pẹ̀lú ọ̀rá ọ̀dọ́-àgùntàn àti ewúrẹ́, pẹ̀lú àgbò irú u ti Baṣani tí ó sì mu ẹ̀jẹ̀ èso àjàrà, àní àti wáìnì.
15 “Mwet lun LEUM GOD elos kasrupi, tusruktu elos orek likkeke lain God; Elos fatelik ke kainmongo lalos. Elos forla liki God su oralosla Ac pilesru Mwet Lango ku lalos.
Jeṣuruni sanra tán ó sì tàpá; ìwọ sanra tán, ìwọ ki tan, ọ̀rá sì bò ọ́ tán. O kọ Ọlọ́run tí ó dá ọ o sì kọ àpáta ìgbàlà rẹ.
16 Alu lalos nu ke ma sruloala oru LEUM GOD El lemta; Orekma koluk lalos akkasrkusrakyal.
Wọ́n sì fi òrìṣà mú un jowú, ohun ìríra ni wọ́n fi mú un bínú.
17 Elos orek kisa nu sin kutu god ma tia pwaye, God sasu ma papa matu tumalos tiana etu kac, Kutu god ma mwet Israel soenna wi alu nu kac.
Wọ́n rú ẹbọ sí iwin búburú, tí kì í ṣe Ọlọ́run, ọlọ́run tí wọn kò mọ̀ rí, ọlọ́run tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ farahàn láìpẹ́, ọlọ́run tí àwọn baba yín kò bẹ̀rù.
18 Elos mulkunla God lalos su langoelos ke ku lulap lal, El su sang moul nu selos.
Ìwọ kò rántí àpáta, tí ó bí ọ; o sì gbàgbé Ọlọ́run tí ó dá ọ.
19 “Ke LEUM GOD El liye ma inge, El arulana kasrkusrak, Ac sisla wen ac acn nukewa natul.
Olúwa sì rí èyí ó sì kọ̀ wọ́n, nítorí tí ó ti bínú nítorí ìwà ìmúnibínú àwọn ọmọkùnrin àti ọmọbìnrin rẹ.
20 El fahk, ‘Nga ac fah tia sifil kasrelos, Na nga fah liye lah mea ac sikyak nu selos, Elos mwet likkeke ac soaru.
Ó sì wí pé, “Èmi yóò pa ojú mi mọ́ kúrò lára wọn, èmi yóò sì wò ó bí ìgbẹ̀yìn in wọn yóò ti rí; nítorí wọ́n jẹ́ ìran alágídí, àwọn ọmọ tí kò sí ìgbàgbọ́ nínú wọn.
21 Elos akkasrkusrakyeyu ke ma sruloala lalos, Ac oru nga in lemta ke sripen god lusrongten lalos, Kutu god su tia god pwaye. Ke ma inge nga fah oru sie mutunfacl lusrongten in akkasrkusrakyalos. Nga fah oru tuh elos in lemtai sie mutunfacl lalfon.
Wọ́n fi mí jowú nípa ohun tí kì í ṣe Ọlọ́run, wọ́n sì fi ohun asán an wọn mú mi bínú. Èmi yóò mú wọn kún fún ìlara láti ọ̀dọ̀ àwọn tí kì í ṣe ènìyàn; èmi yóò sì mú wọn bínú láti ọ̀dọ̀ aṣiwèrè orílẹ̀-èdè.
22 Kasrkusrak luk ac fah ngutyak oana sie e Ac esukak faclu wi ma nukewa ma kapak fac. Ac fah sun acn loallana ke facl lun misa, Ac esukla kapin eol uh. (Sheol )
Nítorí pé iná kan ràn nínú ìbínú mi, yóò sì jó dé ipò ikú ní ìsàlẹ̀. Yóò sì run ayé àti ìkórè e rẹ̀ yóò sì tiná bọ ìpìlẹ̀ àwọn òkè ńlá. (Sheol )
23 “Nga fah sang nu faclos mwe ongoiya wangin saflaiya, Ac orekmakin mwe pisr nukewa nutik lainulos.
“Èmi yóò kó àwọn ohun búburú lé wọn lórí èmi ó sì na ọfà mi tán sí wọn lára.
24 Elos ac fah misa ke masrinsral ac ke musen fol ke mano; Elos ac misa ke mas na keok. Nga ac fah supwama kosro lemnak in anwuk nu selos, Ac wet pwasin in ngalselosi.
Èmi yóò mú wọn gbẹ, ooru gbígbóná àti ìparun kíkorò ni a ó fi run wọ́n. Pẹ̀lú oró ohun tí ń rákò nínú erùpẹ̀.
25 Mweun ac fah oru mwet uh misa inkanek uh; Mwet muta in lohm uh ac tuninfongla. Mukul fusr ac mutan fusr fah misa; Wangin tulik fusr ku mwet matu ac fah moul.
Idà ní òde, àti ẹ̀rù nínú ìyẹ̀wù, ni yóò run ọmọkùnrin àti wúńdíá. Ọmọ ẹnu ọmú àti arúgbó eléwú irun pẹ̀lú.
26 Nga nunku in sukelosla nukewa, In wangin mwet sifil esamulos.
Mo ní èmi yóò tú wọn ká èmi yóò sì mú ìrántí i wọn dà kúrò nínú àwọn ènìyàn,
27 Tusruktu nga tia lungse mwet lokoalok lalos in konkin Mu elos kutangla mwet luk, Ke nga sifacna pa kunauselosla.’
nítorí bí mo ti bẹ̀rù ìbínú ọ̀tá, kí àwọn ọ̀tá a wọn kí ó má ba à wí pé, ‘Ọwọ́ wa lékè ni; kì í sì í ṣe Olúwa ni ó ṣe gbogbo èyí.’”
28 “Israel el sie mutunfacl wangin nanka; Wangin na pwaye etu lalos.
Wọ́n jẹ́ orílẹ̀-èdè tí kò ní ìmọ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí òye nínú wọn.
29 Elos tiana akilenak lah efu ku kutangyukla elos. Elos tia kalem kac lah efu ma inge sikyak.
Bí ó ṣe pé wọ́n gbọ́n, kí òye yìí sì yé wọn kí wọn ro bí ìgbẹ̀yìn wọn yóò ti rí!
30 Efu ku tausin se in kutangyukla sin mwet sefanna, Ac singoul tausin sin mwet luo na? Mweyen LEUM GOD lalos El som lukelos; God kulana lalos El siselosla.
Báwo ni ẹnìkan ṣe lè lé ẹgbẹ̀rún, tàbí tí ẹni méjì sì lè lé ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá sá, bí kò ṣe pé àpáta wọn ti tà wọ́n, bí kò ṣe pé Olúwa wọn ti fi wọ́n tọrẹ?
31 Mwet lokoalok lalos etu na lah god lalos sifacna arulana munas, Tiana ku oana God lun Israel.
Nítorí pé àpáta wọn kò dàbí àpáta wa, àní àwọn ọ̀tá wa tìkára wọn ń ṣe onídàájọ́.
32 Mwet lokoalok lalos kolukla, oana Sodom ac Gomorrah. Elos oana fain in grape ma fokkakin grape mwen ac pwasin,
Igi àjàrà a wọn wá láti igi àjàrà Sodomu àti ti ìgbẹ́ ẹ Gomorra. Èso àjàrà wọn kún fún oró, ìdì wọn korò.
33 Ac wain nimalos oana pwasin ma tuku ke oalin wet uh.
Ọtí wáìnì wọn ìwọ ti dragoni ni, àti oró mímú ti ejò paramọ́lẹ̀.
34 “LEUM GOD El esam ma mwet lokoalok lalos tuh oru; Ac El tupan sie pacl fal in kaelos kac.
“Èmi kò to èyí jọ ní ìpamọ́ èmi kò sì fi èdìdì dì í ní ìṣúra mi?
35 LEUM GOD El ac fah oru foloksak lal ac kaelos; Oasr pacl se ac tuku ke elos ac ikori, Len in ongoiya lalos apkuranme.
Ti èmi ni láti gbẹ̀san. Èmi yóò san án fún wọn ní àkókò tí ẹ̀ṣẹ̀ wọn yóò yọ; ọjọ́ ìdààmú wọn súnmọ́ etílé ohun tí ó sì ń bọ̀ wá bá wọn yára bọ̀.”
36 LEUM GOD El ac fah molela mwet lal Ke pacl se El liye lah ku lalos wanginla. El ac pakomutalos su kulansupwal Ke El ac liye lupan munasla lalos.
Olúwa yóò ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn an rẹ̀ yóò sì ṣàánú fún àwọn ìránṣẹ́ ẹ rẹ̀ nígbà tí ó bá rí i pé agbára wọn lọ tán tí kò sì sí ẹnìkan tí ó kù, ẹrú tàbí ọmọ.
37 Na LEUM GOD El ac fah siyuk sin mwet lal, ‘Pia god kulana lowos ma kowos lulalfongi uh?
Yóò wí pé, “Òrìṣà wọn dà báyìí, àpáta tí wọ́n fi ṣe ìgbẹ́kẹ̀lé e wọn,
38 Kowos kitalos ke mwe mongo yuyu ke mwe kisa lowos Ac sang wain ma kisakinyuk elos in nim. Inge, lela god ingan in tuku kasrekowos, Ac molikowosla.
ọlọ́run tí ó jẹ ọ̀rá ẹran ẹbọ wọn tí ó ti mu ọtí i wáìnì ẹbọ ohun mímu wọn? Jẹ́ kí wọn dìde láti gbà wọ́n! Jẹ́ kí wọn ṣe ààbò fún un yín!
39 “‘Liye, nga mukefanna pa God; Wangin pac sie god sayuk. Nga uniya ac nga sang moul, nga kanteya ac nga akkeyala, Ac wangin sie ku in lain ma nga oru.
“Wò ó báyìí pé, Èmi fúnra à mi, Èmi ni! Kò sí ọlọ́run mìíràn lẹ́yìn mi. Mo sọ di kíkú mo sì tún sọ di ààyè. Mo ti ṣá lọ́gbẹ́ Èmi yóò sì mu jiná, kò sí ẹni tí ó lè gbà kúrò lọ́wọ́ ọ̀ mi.
40 In oana ke nga pa God moul, Nga sralak pouk ac wulela ku
Mo gbé ọwọ́ mi sókè ọ̀run mo sì wí pé, Èmi ti wà láààyè títí láé,
41 Lah nga fah tamla cutlass saromrom nutik Ac liyaung tuh nununku suwohs in orek. Nga fah foloksak nu sin mwet lokoalok luk Ac kaelos su srungayu.
nígbà tí mo bá pọ́n idà dídán mi àti tí mo bá sì fi ọwọ́ mi lé ìdájọ́, Èmi yóò san ẹ̀san fún àwọn ọ̀tá mi Èmi ó sì san fún àwọn tí ó kórìíra à mi.
42 Sukan pisr nutik fah tultul ke srah kaclos, Ac cutlass nutik fah onelosi nukewa su lainyu. Nga fah tia likiya moul lun kutena mwet su lainyu; Finne mwet pakpuki ke cutlass, wi mwet sruoh ke mweun, elos nukewa fah misa.’
Èmi yóò mú ọfà mu ẹ̀jẹ̀, nígbà tí idà mi bá jẹ ẹran: ẹ̀jẹ̀ ẹni pípa àti ẹni ìgbèkùn, láti orí àwọn aṣáájú ọ̀tá.”
43 “Kowos mutanfahl uh, kowos in kaksakin mwet lun LEUM GOD— El kalyaelos nukewa su onelosla. El foloksak nu fin mwet lokoalok lal, Ac El nunak munas ke ma koluk lun mwet lal.”
Ẹ yọ̀ ẹ̀yin orílẹ̀-èdè, pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ̀ nítorí òun yóò gbẹ̀san ẹ̀jẹ̀ àwọn ìránṣẹ́ ẹ rẹ̀; yóò sì gbẹ̀san lára àwọn ọ̀tá a rẹ̀ yóò sì ṣe ètùtù fún ilẹ̀ àti ènìyàn rẹ̀.
44 Moses ac Joshua, wen natul Nun, eltal fahkak kas ke on soko inge tuh mwet Israel nukewa in ku in lohng.
Mose sì wá ó sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ òfin yìí ní etí àwọn ènìyàn náà, òun, àti Hosea ọmọ Nuni.
45 Ke Moses el aksafyela luti lal ke kas lun God nu sin mwet uh
Nígbà tí Mose parí i kíka gbogbo ọ̀rọ̀ wọ̀nyí sí Israẹli.
46 el fahk, “Aklohya in akos sap inge nukewa ma nga sot nu suwos misenge. Kalweni nu sin tulik nutuwos tuh elos in ku in oaru ac akos mwe luti nukewa lun God.
Ó sọ fún un pé, “Ẹ gbé ọkàn an yín lé gbogbo ọ̀rọ̀ tí mo ti sọ láàrín yín lónìí, kí ẹ̀yin lè pàṣẹ fún àwọn ọmọ yín láti gbọ́rọ̀ àti láti ṣe gbogbo ọ̀rọ̀ inú òfin yìí.
47 Mwe luti inge tia kas lusrongten — a moul na lowos. Akos ma inge ac kowos fah moul paht fin facl se lefahl ingo Infacl Jordan ma kowos apkuran in oakwuki we.”
Wọn kì í ṣe ọ̀rọ̀ asán fún ọ, ìyè e yín ni wọ́n. Nípa wọn ni ẹ̀yin yóò gbé pẹ́ lórí ilẹ̀ tí ẹ̀yin ń gòkè e Jordani lọ láti gbà.”
48 In len sacna LEUM GOD El fahk nu sel Moses,
Ní ọjọ́ kan náà, Olúwa sọ fún Mose pé,
49 “Fahla nu Fineol Abarim in acn Moab tulanang siti Jericho. Fanyak Fineol Nebo ac ngetla liye facl Canaan ma nga akola in sang nu sin mwet Israel.
“Gòkè lọ sí Abarimu sí òkè Nebo ní Moabu, tí ó kọjú sí Jeriko, kí o sì wo ilẹ̀ Kenaani, ilẹ̀ tí mo ń fi fún àwọn ọmọ Israẹli, bí ìní i wọn.
50 Kom ac fah misa fineol soko an oana ke Aaron, tamulel lom, el misa Fineol Hor,
Ní orí òkè tí ìwọ ń gùn lọ ìwọ yóò kùú níbẹ̀, kí a sì sin ọ́ pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ, gẹ́gẹ́ bí arákùnrin in rẹ Aaroni ti kú ní orí òkè Hori tí a sì sin ín pẹ̀lú àwọn ènìyàn an rẹ̀.
51 mweyen komtal kewa tuh fahsr sayen ma nga sapkin nu sumtal ye mutun mwet Israel. — Pacl se komtal tuh muta ke kof in acn Meribah, apkuran nu ke siti Kadesh in acn mwesis Zin, komtal tuh tia akfulatyeyu ye mutun mwet uh.
Ìdí ni pé ẹ̀yin méjèèjì ṣẹ̀ sí mi láàrín àwọn ọmọ Israẹli ní ibi omi Meriba Kadeṣi ní aginjù Sini àti nítorí ẹ̀yin kò yà mí sí mímọ́ láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
52 Kom ac ngetla liye facl sac ke oan loessula, tusruktu kom ac tia ilyak nu in facl sac su nga ac sang nu sin mwet Israel.”
Nítorí náà, ìwọ yóò rí ilẹ̀ náà ní ọ̀kánkán, o kì yóò wọ inú rẹ̀ ilẹ̀ ti mo ti fi fún àwọn ọmọ Israẹli.”